TB Joshua Burial: Wolii Synagogue SOAN jẹ́ Akàndá ẹ̀dá- Oba Enitan Ogunwusi, Ooni Ile Ife
Ifẹ ni akoja ofin, eyi ti Wolii TB Joshua ni lọpọlọpọ- Olori Naomi Ogunwusi
Lẹyin o rẹyin, Wolii Temitope Balogun Joshua wọ kaa ilẹ lọ sinmi.
Opọlọpọ awọn eekan ilu lo peju pesẹ sibi ayẹyẹ eto ikẹyin ti wọn se fun olori ijọ Synagogue SOAN naa.
Olori Naomi Silekunola to soju Ooni ti Ile Ife sapejuwe Wolii naa bi alaanu ti o nifẹ ara ilu pupọ.
- 'Ẹ wòó, ẹ máa retí ìdájọ́ àwọn olùwọ́de Yoruba Nation 49 tó wà láhàmọ́ Ọlọ́pàá ní ọjọ́ ...'
- Mo fẹ́ kí a dá Yorùbá Nations sílẹ̀ kí a lè máa mójútó àwọn adarí tó bá kọsẹ́ fúnra wa- Peter Fatomilola
- Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ tí adigunjalè bá kọ lẹ́tà sí yín pé àwọn fẹ́ ẹ́ wá jà yín lólè
- Sínímá Abebi tí mo kọ́kọ́ ṣe jẹ́ ẹ̀bùn ọjọ́ ìbí tí Ìyá mi fún mi- Fisayo Amodemaja
- Àrá kọ ṣàràà! Ó sán pa èèyan 16 tó ń ya "Selfie" lórí ilé gogoro

Oloye Aladun, Oloye Zaki ti Akoko ni ipinle Ondo ti Wolii TB Joshua ti wa naa ba BBC Yoruba sọrọ lorukọ awọn oloye to ku ti wọn jọ wa si Eko.
O sọrọ nipa ipa ribiribi ti Wolii TB Joshua ko ni Arigidi Akoko ati ohun to se laye awọn ara ilu Akoko.

Bisoobu Tunde Adegbite to jẹ alaga ẹgbẹ ọmọleyin Jesu CAN ni ipinlẹ Eko naa sọrọ pupọ lori Wolii TB Joshua.
Bisoobu naa salaye pe TB Joshua pa ọpọlọpọ lerin nigba aye rẹ.
Koda, o salaye bi Wolii naa se bẹrẹ iṣẹ iranṣẹ rẹ ko to di nla bayii ni Eko.
- 'Ọkọ̀ ojúomi Noah kò gbádùn tó, làwọn ẹ̀ṣọ́ orí omi fi dèé mọ́lẹ̀ ní Ipswich''
- Wo àwọn òjíṣẹ́ Ọlọrun jàǹkàn ní Naijiria tí kò yọjú síbi ayẹyẹ ètò ìsìnkú TB Joshua
- CAN faraya lórí ikọlù agbofinro sàwọn ajàfẹ́tọ̀ bí Sunday Igboho
- "Kò sí Pásítọ̀ tó ṣiṣẹ́ ìyanu, tó lé ẹ̀mí èṣù jáde bíi TB Joshua"
- A ń gbóhùn àdúrà sókè ní orílẹ̀èdè 127 lágbàáyé torí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Baptist tí wọ́n jígbé ní Kaduna -Baptist Convention

Aposle Abiodun Sanya Olu to ṣoju alaga Christian Association of Nigeria lapapo CAN Nigeria naa sọrọ nipa oloogbe TB Joshua.
Apostle ni sebi orukọ Jesu ni TB Joshua fi n se gbogbo nakn to n se laye ki ọlọjọ to de.
- "Gbàjarè! Àwọn èèyàn tí DSS kó nílé Sunday Igboho nílò ìtọ́jú kíámọ́sá"
- Ó dùn wá gaan pé wọn kò gbé òkú TB Joshua wá sílé, bó ṣe ọgọ́rùn ún ọdún, a ṣì ń retí - Àwọn ìyàwó ilé
- 'Àwọn orí eku àti ohun ìni wa tó bàjẹ l'Ọ́jà Bode toríi Táńkà gáàsì tó ya wọlé kìí ṣe kékéré, ẹ ṣàánú wa o!'
- Ìjọba mọ̀ pé àwọn Fulani ń wa góòlù ní Owo láì ṣe nǹkan kan si - Olowo
- Ṣé o lè gbé orí rẹ lọ sọ́dọ̀ fárífárí alábẹ kó dán bí àwọn tó ní àwọn kò lè lo "clipper láéláé yìí?
O ni nitootọ TB Joshua ko darapọ mọ ẹgbẹ ọmọleyin Kristi CAN sugbọn o n ṣiṣẹ iyanu loruko Jesu naa ni.
Apostle Abiodun ni adura lo ku ki awa ti a wa laye maa gba lori iṣẹ ọwọ wa ati nigba ti ọlọjọ ba de.
