Fisayo Amodemaja: Nínú eré 'Children Day' ní Sọ́ọ̀ṣì ni Abebi ti bẹ̀rẹ̀ eré ṣiṣe- Bukola
Oluwafisayomi Amodemaja jẹ ọdọmọde oṣere to tun gbe fiimu ara rẹ jade gẹgẹ bii olootu ere.
Fiimu Abebi to kọkọ gbe jade jẹ eyi to sapejuwe pe o da lori iwa ipa ninu idile ati ipa to n ni lara awọn ọmọ nibẹ.
Abebi ni Iya oun, Bukola Amodemaja ni orisun iwuri oun.
- Kò sí ẹni tí mo fura sí lórí ikú ọkọ mi, àmọ́...- Adebisi aya Titus Ejanla tí wọ́n pa ní Ibadan
- Àwọn Bòròró agbébọn ló pa Fulani ọmọ mi, a kọlù wọ́n lá fi rí eèyàn méjì gbà nínú àwọn tí wọ́n jígbé ní Ajowa-Baba Fulani
- Ẹyìn tẹ ń gba ojú VPN wọ Twitter, ẹ kò ṣé mí, ará yín lẹ̀ ń ṣé - Lai Mohammed
- Àwọn lọ́balọ́ba nílẹ̀ Yoruba dalẹ̀ wa lórí àwọn ọmọ OPC mẹ́ta tí wọ́n tímólé láìṣẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Iskilu Wakili - Ẹgbẹ́ OPC
- Mo fẹ́ kí a dá Yorùbá Nations sílẹ̀ kí a lè máa mójútó àwọn adarí tó bá kọsẹ́ fúnra wa- Peter Fatomilola
Awọn miran to kopa ninu ere ọdọmọde yii ni Bimbo Oshin, Odunlade Adekola ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Lọdun 2018 ni Fisayo Amodemaja bẹrẹ ere ṣisẹ.
- Ẹlẹ́hà tó ń ró aṣọ tí kò bo ìdí rẹ̀ kìí ṣe aya ti wa ní Ilorin- Batimoluwasi Oníwákà
- Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo àti àwọn ẹlẹ́sìn àbáláyé bẹ̀rẹ̀ àjọṣepọ̀ láti fí opin sí ìṣoro ètò aàbò
- Kó sí ààyé fún ìdíbò ''Referendum'' nínú Ìwé Òfin Naijiria, dídádúró ilẹ̀ Yoruba Nation yóò nira- Amòfin
- Gọngọ́ sọ, àwọn Ṣọ́jà lé ọlọ́pàá lùgbẹ́ lágọ́ ọlọ́pàá l' Osogbo
- Ilé ẹjọ́ gba béèlì Baba Ijesha N2Miliọ̀nù ní wọ́n fún
Lati ara kikopa ninu ere ọmọde nile ijọsin ni Sọọsi lasiko ayajọ Children Day ni iya rẹ ni o ti bẹrẹ ere.
Abebi sọ afojunsun rẹ lọjọ iwaju ati pe ko di iwe kika oun lọwọ.
Bukola Amodemaja gba obi ati alagbatọ nimọran lati tubọ gbadura fun ọmọ wọn ki wọn si gbaruku ti wọn ninu talẹnti wọn.
- Iyabo Ojo, mẹ́nu kúrò lórí ọ̀rọ̀ Baba Ijesha ní báyìí tí ọ̀rọ̀ ti dé iwájú mi - Adájọ́ Toyin Taiwo
- Àwọn adigunjalè kọ lẹ́tà sí adúgbò, wọ́n ni kí ara àdúgbò dá 20m tàbí kí wọ́n ó jàwọ́n lólè
- Mó ṣèlérí láti buwọ́lu àtúntò Naijiria, Ilé Aṣòfin o kù sí ọwọ́ yín - Ààrẹ́ Buhari
- Èèyàn kan ti kú, 99 di àwátì lẹ́yìn tí ilé alájà méjìlá wó lulẹ̀ l'óru





