Olowo of Owo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tó yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Olowo tilu Owo, Ọba Ajibade Gbadegesin ti ke si ijọba lati wa nnkan se nipa awọn Fulani to n wa goolu ni Owo.
Ọba Gbadegesin, lasiko ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba ni o yẹ ka se akoso Naijiria gẹgẹ ba se fọwọsowọpọ gba ominira.
O ni ohun toju awọn to n pe fun idasilẹ Yoruba Nation ri, lo mu ki wọn maa pariwo fun iyapa Naijiria.
- Ọlọ́run fi ẹ̀mí Sunday Igboho ta gbogbo àwa tókù jí ni, ọ̀rọ̀ yìí ti kọjá ìsòpọ̀ Nàìjíríà - Oba Gbolahan Shomolu
- Ìjọba Buhari ti gbẹ́rù tó kọjá orí, bàtá tó bá ń ró lákọ fẹ́ ya ni!- Tunde Bakare
- Abiola Ajimọbi ní ti mo bá di gómìnà, òun á ṣẹ̀wọ̀n ni- Adebayo Shittu
- Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999? BBC tú àlàyé síta
- A ti ṣetán láti fi ẹ̀mí wa lélẹ̀ fún òmìnira ilẹ̀ Yoruba, a ò níbi kankan ti a fẹ́ sálọ - Ọba Adetokunbo Tejuosoho
- Bíi ti UK, USA, Germany, France lẹ ó lè ṣe ẹ̀sìn tó bá wù yín yàlàyòlò ní orílẹ̀èdè Yorùbá Nation - Igboho
- Akintoye sá lọ Amẹrika lásìkò ìjọba ológun, ó wá fẹ́ da Naijiria rú báyìí - Akeredolu
Olowo fikun pe ti ijọba ba se atunto to yẹ, Sunday Igboho yoo dakẹ, ti yoo si fọwọsowọpọ pẹlu ijọba.
Bakan naa lo woye pe ọpẹlọpẹ pe ikọ alaabo Amotekun to ti wa saaju akoko yii, bibẹẹ kọ, Ọlọrun lo mọ ohun ti oju awọn eeyan ipinlẹ Ondo ko ba ri tori eto aawo to mẹhẹ.
Ọba Gbadegesin wa rọ ijọba lati gba eto atunto Naijiria laaye, ki ohun gbogbo le tuba tusẹ.




