Ààrẹ Muhammadu Buhari tí ṣe àtúntò àwọn mínísíta rẹ̀

Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Ààrẹ Muhammadu Buhari tí buwọ́lu àtúntò àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ aláṣẹ ìjọba tó yàn sípò ni ọjọ́ kọkànlélógún, ọdún 2019.
Nínú àtẹ̀jáde kan sì àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ aláṣẹ nínú ìpàdé tó wáyé lọ́jọ́ru, ọjọ́ kini oṣù Kẹ̀sán, ni ààrẹ̀ tí kéde ayipada ọhun.
Atẹjade naa ni Mohammad Sabo Nanono to je mínísíta fún iṣẹ́ ọ̀gbìn àti ìdàgbàsókè ìgbèríko àti ónímọ̀ ẹ̀rọ Sale Mamman tó jẹ́ mínísíta ọ̀rọ̀ àmúșagbára, n kúrò nínú ọmọ ìgbìmọ̀ aláṣẹ ìjọba.
- UK ya kúrò lára EU, Yorùbá le yapa lára Nàíjíría tí kò bá sí ìwé òfin tuntun - Gbadamosi, Ilana Omo Oodua
- O ti di èèwọ́ láti ṣẹ̀ oyún lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ mẹ́fà ní ìpínlẹ̀ yìí
- Buhari, àbẹ́rẹ́ àjẹsára kàńpá kọ́ ló kàn bí kò ṣe ko kọ́kọ́ mú ara dẹ ìlú - Aráàlú faraya
- Wo ìpínlẹ̀ mọ́kànlá tí ìdaranjẹ̀ ti di èèwọ̀ ní gúúsú Nàíjíríà
- "Alhaji Fatai, ti DSS pa nílé Sunday Igboho ni kò ríran"
- Irọ́ ní, Taskforce ló ń gba owó gọbọi lọ́wọ́ awakọ̀ Eko, kìí ṣe àwa - LASTMA
- Afurasí ajínigbé dèrò ọrun, òmíràn kó sí pańpẹ́ ọlọ́pàá l’Ogun
- Ṣe ìgbọ̀nsẹ̀ sí gbangba òde, kóo rugi oyin lábẹ́ òfin tuntun
Bákan náà ni mínísíta fún ètò àyíká, Mohammed Mahmood Abubakar yóò lọ gba iṣẹ́ mínísíta ètò ọ̀gbìn àti ìdàgbàsókè àyíká.
Nígbà tí onímọ̀ ẹ̀rọ Abubakar Aliyu yóò bọ́ si ipò mínísíta iná àmúșagbára.
Àtúntò ààrẹ yìí kò sẹ́yìn ìlànà ìjọba Muhammadu Buhari tó má ń ṣe àtúnyẹ̀wò àwọn iṣẹ́ ìjọba nípa bí àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ ṣe má ń ṣe ìpàdé àti ìpàgọ́ láti fikulukù.
Ó fi kún pé ìpàdé yìí lọ jẹ̀ kí àwọn rí ibi tí ìdàgbàsókè de ba, ti àwọn ìhà tó kú díẹ̀ káàtó fún àti ọ̀nà láti mú ìdàgbàsókè bá ètò ọ̀rọ̀ ajé àti láti mú ojúlówó àṣeyọrí bá àwọn ọmọ Nàìjíríà.
Ó pari atgẹjade naa pé ní àìpé yìí ìjọba yóò yàn àwọn ènìyàn tuntun láti rọ́pò àwọn ayé tó ṣì sílẹ̀ ni ìlànà tí òfin fi lélẹ̀
- Ọ̀pọ̀ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù mójú lọ sọ́jà, bí kátàkárà agbábọ́ọ́lù ṣe dópin
- Àṣírí tú lórí ìdí tí DSS kò ṣe fi mẹ́rin sílẹ̀ nínú amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ Sunday Igboho - Amòfin Olajengbesi
- Akeredolu buwọ́lu òfín máfi ẹran jẹko láàrín ìgboro l'Ondo
- Ìmáàmú àgbà kan ní Abuja ti fi ìbínú sọ̀rọ̀ sí Buhari torí ìkọlù agbébọn
- O kò ní wọ ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí tó ò bá gba abẹ́rẹ́ Covid-19 - Ìjọba Ondo













