Ìyàwó lè lo ọwọ́ rẹ̀ fi ba ọkọ ṣeré lásìkò Halaada rẹ̀, èyí kò ba ẹ̀sìn jẹ́- Aafa Abdullateef Lanre
Aafa Abdullateef Lanre tun menuba awon sitaili ibalopọ ti ko ba ẹ̀sin Islam jẹ laarin lọkọlaya
Lori ọpọlọpọ ibeere ti a gba nipa ọna ibalopọ to tọna ni BBC ṣe wa Aafa Abdullateef Lanre to jẹ akọṣẹmọṣẹ nipa ọrọ ibalopọ to tun jẹ onimọ ninu ẹsin Islam kan.
Aafa yii ṣalaye pe ọna meji ni oju ti awọn onimọ Islam fi wo ibalopọ alafi-ẹnu-ṣe ti oloyinbo n pe ni: Oral Sex
- Egbẹ́ òṣìṣẹ́ iná mọ̀nàmọ́na ti wọ́gilé ìyanṣẹ́lódì wọn lẹ́yìn tíjọba ṣèlérí pé..-
- Tinubu ti ṣàdúrà fún ìran Yorùbá láti Abeokuta, Dapo abiodun ni pé Tinubu ló kàn ni 2023
- Ọmọ mẹ́rin bómilọ níbùdó ìgbafẹ́ etí òkun kan l'Eko
- Irú ọmọ wo ní Yorùbá ń pè ní Olúgbódi?
- Àlàyé rèé lórí ohun tó fa ìpàdé tó ń wáyé lọ́wọ́ láàrín Obasanjo, Tinubu, àtawọn ọbalayé ilẹ̀ Yorùbá l'Abeokuta

Kini Onimo yii tun salaye lori re?
Aafa Abdullateef Lanre tun sọrọ nipa koko pe ọkunrin ni anfani ninu Islam lati fẹ obinrin titi de ori mẹrin.
Ati pe ti iyawo rẹ kan ko ba fẹran ibalopọ alafienu se, yoo ri obinrin mii ti o fẹran rẹ ki ot o fẹ iyawo de merin.
Ni afikun, iru okunrin bẹẹ ko lẹtọ lati kọ iyawo ti ko ba fẹran ibalopọ alafiẹnu ṣe sile rara ninu Islam.
- Owó oṣù 'Professor' ju ti 'Perm Sec' lọ nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní 1963- Emeritus Ayo Bamgbose
- Bí ikú ilé kò bá pani...ìkìlọ̀ rèé fún ẹ̀yin ọmọ Yorùbá tí ẹ n gbàbọ̀dè f'ájínigbé- Oba Francis Alao
- Yuroopu ni wọ́n sọ pé à ń lọ ṣùgbọ́n Morocco ni mo ti bá ara mi nínú iṣẹ́ aṣẹ́wó- Abosede
- Egungun Oloolu ti ilẹ̀ Ibadan fojú han aráyé! Gbọ́ àwọn ǹkan tó ń dẹ́rù ba obìnrin, ọmọde nípa rẹ̀ àti èèwọ̀ rẹ̀
- Bàbá Orlando Owoh ti lọ kí n tó bẹ̀rẹ̀ sí ní lo ohùn orin wọn fi ṣe oríire láyé - Orlando Ore
- Wo ìgbẹ̀yìn àwọn ọlọ̀tẹ̀ Yorùbá tó ran Fulani lọ́wọ́ láti kógun ja ìlú Osogbo
Kini Islam sọ nipa ibalopo alafienu se?
O ni Laarin Halaali ati Haraamu ni ibalopo alafẹnuṣe wa.
Labẹ Shariah, Haram ni nkan ti a ko faaye gba. Halal ni eleyi ti a faaye gba.
Eyi to ṣe pe bi a koba ṣe e, a o gba laada. Bi a ba si ṣe e ko si ijiya fun wa ni wọ n n pe ni Makrooh.
- Mọ̀ síi nípa àwọn aláwàdá Yorùbá tó ti dolóògbé ṣùgbọ́n tí ayé ṣì n pariwo wọn
- Mo pàṣẹ̀ ètò aàbò tó gbóòrìn ní gbogbo iléẹ̀kọ́, iléèwòsàn lásìkò yìí- Alkali olórí ọlọ́pàá Nàìjíríà
- Mó dìtẹ̀ ìṣèjọba Jonathan torí òṣèlú- Adams Oshiomhole
- Wọ́n tí sìn Páṣítọ́ Shuaib Busari tí àwọn adigunjale ṣekúpa niluu ibadan
- Kò sí ẹlẹ́gbẹ́ Atiku láàrín Tinubu àti Obi - Dino Melaye
- Ẹgbẹ́ NLC kọ lẹ́tà sí Buhari pé kó fi ìdá àádọ́ta 50% kún owó oṣù òṣìṣẹ́ Nàìjíríà
Aafa Abdullateef sọ pe ọkọ ko le kọ aya rẹ silẹ nitori pe ko fẹran ibalopọ alafenuse sugbon Islam faaye gba ọkunrin to ba kundun rẹ lati fẹ iyawo de ori mẹrin ninu eyi ti yoo ti ri obinrin ti oun naa fẹran iru ibalopọ bẹẹ.