Ìròyìn Kàyééfì BBC Yorùbá: Bí Ọba aládé ṣe jàjà bọ́ lọ́wọ́ àwọn afurasí ajínigbé

Kabiyesi Osi
Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 1
Skip Facebook post

Content is not available

View content on FacebookBBC kò mọ̀ nípa àwọn ohun tí ó wà ní àwọn ojú òpó tí ó wà ní ìta.

End of Facebook post

Lori eto iroyin Kayeefi BBC Yoruba lọsẹ yii, a mu itan nipa bi awọn ajinigbe darandaran ti ṣe fẹ gbiyanju lati ji Ọba Alade gbe nilẹ Yoruba.

Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́

Kabiyesi onirẹsi ilu Irẹsini ipinlẹ Ondo, Oba David Olajide ni Oba Alade ti a ba sọrọ ti wọn si tu kẹkẹ ọrọ kalẹ nipa bi awọn Fulani darandaran kan ti ṣe n ṣọṣẹ lagbegbe rẹ.

Kayeefi

Ọrọ awọn darandaran to ti fẹ di ọdaran nilẹ Yoruba jẹ ohun ti o n kọ awọn eeyan lominu.

Ẹ wo fidio naa ni ẹkunrẹrẹ ninu fọ́nrán tó wà lókè yìí.

Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi