El-Rufai: Ọjọ́ mẹ́rin láàárín ọ̀ṣẹ̀ ní àwọn òṣìṣẹ́ yóò máa lọ sí ibi iṣẹ́ báyìí'

Ijọba ipinlẹ Kaduna ti kede pe ọjọ mẹrin laarin ọṣẹ ni awọn oṣiṣẹ yoo maa lọ si ibi iṣẹ bẹrẹ lati Ọjọ Kini, Osu Kejila, ọdun 2021.
Gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai ni igbesẹ yii yoo mu irọrun ba awọn oṣiṣẹ lati ṣe iṣẹ wọn bi iṣẹ.
Bakan naa ni Gomina naa fikun un pe eyi yoo ran awọn oṣiṣẹ naa lọwọ lati le faramọ mọlẹbi wọn ju ti tẹlẹ lọ nitori wọn yoo ri aye lati lo pẹlu wọn ninu ile.
- Jumoke Oyeleke: Iya Jumoke kọ̀ láti lọ ilé tí ìjọba rẹ́ǹtì, ó ní òun ò lè padà sí ẹ̀sẹ̀ àárọ̀ lẹ́yìn ilé mè-rẹ́ẹ̀ǹtì
- Wo ọ̀nà táwọn olólúfẹ́ Baba Suwe ní London àti Manchester fẹ́ gbà ṣẹ̀yẹ ìkẹyìn fun
- BBC Africa Eye: Ìwádìí tú àṣírí bí ààrẹ orílẹ̀-èdè DR Congo ṣé lú owó aráàlú ní pónpó
- Timothy Adegoke: Kò pẹ́ táa bẹ̀rẹ̀ ẹ̀jọ́ lórí ikú àbúrò mi ni Adedoyin tó ni hòtẹ́ẹ̀lì rán lawyer kó gbé owó wá - Ẹ̀gbọ́n Timothy
Ninu atẹjade ti oluranlọwọ pataki fun gomina El-Rufai, Muyiwa Adekeye fi lede ni Osu Kejila ni erọngba ijọba yii yoo hggberaso.
O ni lati Osu Kẹjila ni awọn oṣiṣẹ ijọba yoo bẹrẹ si ni ṣiṣẹ lati aago mẹjọ owuro titi di aago marun un irọlẹ ni Ọjọ Aje si Ọjọ Ẹti.
Amọ ni Ọjọ Ẹti, gbogbo oṣiṣẹ yatọ si awọn to n ṣiṣẹ ni awọn ileewe ati ileewosan ni yoo ṣi'sẹ lati ile.

Oríṣun àwòrán, Kaduna state govt
Ijọba ipinlẹ Kaduna fikun un pe bi awọn oṣiṣẹ yoo ṣe ma a ṣiṣẹ ni yii titi di igba ti awọn yoo ṣe atuntọ iye ọjọ ti awọn oṣiṣẹ yoo fi ṣiṣẹ naa, eleyii ti yoo jẹ ọjọ mẹrin.
''Igbesẹ ijọba yii jẹ ọkan lara awọn ẹkọ ti ijọba kọ lara ajakalẹ arun Covid-19, eleyii to mu ki ajakalẹ arun naa ma ni ipa buburu nibẹ.''
- "Ààbò ọgbà ẹ̀wọ̀n Jos lágbára, kàyéèfì ní bí agbébọn ṣe kọ lù ú"
- Àwọn àjòjì ṣá obìnrin tó ń lọ gbálẹ̀ Ṣọ́ọ̀ṣì Deeper Life pa, ẹ̀jẹ̀ bo gbogbo ara rẹ̀
- Abiyamọ, ọmọ rẹ̀ àti èèyàn kan bá ìbúgbàmù ọkọ́ aképo lọ́ ní Lafenwa
- Wo ọ̀ná tí àwọn ọkùnrin lè gbà ṣe ìfètòsọ́mọbíbí láì lo kọ́ndọ́ọ̀mù lásìkò ìbálòpọ̀
- Mí ò polongo ìdupo ààrẹ ọdún 2023 fún Tinubu-Foluke Daramola
- Àwọn agbébọn tó yabo ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Jos há síbẹ̀ lẹ́yìn tí agbófinró yí wọn ká
- Kí ló yẹ kóo sáré ṣe bí ejò bá ṣá ọ jẹ?
- Ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí àwọn olólùfẹ́ yìí tí wọ́n bá okú wọn ní ilé ìgbọ̀nsẹ̀ wọn
''Bakan naa ni asiko ajakalẹ arun naa fihan pe awọn oṣiṣẹ gbọdọ wa ọna tuntun miran lati ṣe iṣẹ wọn ki wọn ba le ṣe ni aṣeyọri.''
Gomina ipinlẹ Kaduna ni ọna tuntun yii yoo jẹ ki awọn oṣiṣẹ kunjuwọn nipa lilo ọna igbalode lati ṣe iṣẹ wọn.















