NIN registration: Ìjọba Nàìjíríà ti sún ọjọ́ ìforúkọsílẹ káàdi ìbánisọ̀rọ̀ síwájú síi

Oríṣun àwòrán, others
Ijọba Naijiria ti kede laarọ oni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ keji, oṣu keji, ọdun 2021 pe wọn ti fi kun asiko iforukọsilẹ ti wọn kede tẹlẹ.
Eto iforukọsilẹ yii ni lati ni idanimọ gbogbo awọn to n lo kaadi ipe ori foonu ni Naijiria.
Ọsẹ mẹjọ ni ijọba Naijiria fi kun gbendeke naa ki op le tubọ rọrun sii fawọn eniyan Naijiria lati le forukọsilẹ paapaa lasiko ajakalẹ arun coronavirus yii.
- Ẹ̀wọ̀n ọdún méje ni fún ẹni tó bá gba owó lọ́wọ́ rẹ̀ fún NIN - NIMC
- Àfàìmọ̀ ká máa dá ìforúkọsílẹ NIN dúró tórí ewu coronavirus- Mamora
- Ìjọba àpapọ̀ ti kéde ìsúnsíwájú ọjọ́ ìforúkọsílẹ̀ nọ́mbà NIN
- Buhari, pàṣẹ fún Pantami kó lọ tọwọ́ ọmọ rẹ̀ bọ aṣọ lórí ìforúkọsílẹ̀ NIN-SERAP
- Wo àdánù tó wà nínú gbígba ayédèrú áápù fún ìforúkọsílẹ̀ NIN lórí ayélujára
Saaju ni ijọba ti kede ọjọ kesan an, oṣu keji tẹlẹ ki wọn to sun un di oṣu kẹrin bayii.
Oludari ẹka gbogboogbo ni ileeṣẹ ijọba to n mojuto eto iforukọsilẹ naa Nigerian Communications Commission, Ikechukwu Adinde, lo fi ọrọ naa sita.
Adinde ṣalaye pe o di dandan ki wọn fi asiko kun igba iforukọsilẹ naa nitori pe awọn eeyan n kun lori ero to pọ nibudo iforukọsilẹ ati awọn kudiẹ kudiẹ mii to nilo asiko sii lati yanju ni irọrun fun awọn oluforukọsilẹ.
Isa Patami to jẹ minista ileeṣẹ ijọba apapọ lori ona ibaraẹnisọrọ naa ṣalaye nipa bo ṣe ṣe pataki lati fi kun asiko naa.
Patami sọ eyi di mimọ lasiko to n ṣe ipade pẹlu ikọ to n mojuto ọrọ itankalẹ ajakalẹ arun Coronavirus lọjọ kinni, oṣu yii.
- Òfin kónílé-ó-gbélé gbòde nílùú Igangan lórí ẹ̀rù pé Fulani le k'ógun wá lẹ́yìn àbẹ̀wò Igboho
- Ṣé o fẹ́ lo òògùn ìfètò sọ́mọ́ bíbí? Wo ipa tó le ní lára rẹ kí o tó lò ó
- Ẹ̀yin awakọ̀ tí ẹ máa ń tẹ fóònù lórí ìrin ti rugi oyin l'Eko- FRSC
- Ṣé lóòtọ́ọ́ láwọn Fulani tún ṣá aráàlú Igangan méjì ládàá nígbà tí wọ́n ń sùn?
- Gomina Seyi Makinde ṣe ìpàdé lóru mọ́jú pẹ̀lú àwọn eèyàn Ibarapa ní Oke Ogun
- ''Ìjọba gbọ́dọ̀ fí òfin dé ìrìnàjò àwọn Fulani darandaran láti àríwá sí gúúsù Nàíjíríà''
- Gomina Seyi Makinde ṣe ìpàdé lóru mọ́jú pẹ̀lú àwọn eèyàn Ibarapa ní Oke Ogun














