Yoruba Film: Ta ló leè dúró s'ẹ́gbẹ̀ẹ́ Okunnu láì rẹ́rìn ín?

Oríṣun àwòrán, okunu_1
Laipe Okunnu ṣe ọjọ́ ibi, iyen Wale Akorede ti ọpọ eniyan mọ si Okunnu latara gbogbo ere ẹfẹ rẹ to ma n ṣe.
Gbajumọ ni laarin awọn oṣere Yoruba, o si jẹ ọmọ bibi ilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo.
Wọn bi i lọjọ Karun, oṣu Kọkanla ọdun 1967.
Ẹwẹ, ati ilu Oyo ati Ogbomoṣo lo ti dagba, to si bẹrẹ si ni ṣe ọmọkunrin.
This article contains content provided by Instagram. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read Instagram cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of Instagram post
- Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
- Ta ló lè ṣe ẹ̀fẹ̀ tó Mr Latin láàrin àwọn apanilẹ́rìín fíìmù Yorùbá?
- K-unle Afolayan sọ̀rọ̀ sókè nípa nípa sinimá Anikulapo
- Ẹnikẹ́ni tó ń lo pátákó alákọ̀ọ́lé "No parking" ń fi gbaga òfin ṣeré - Ọlọ́pàá Nàìjíríà
- -Ọkọ mi kò ráyè wọ ojú ara mi láti já ìbálé lẹ́yìn oṣù kan ta ṣe ìgbéyàwó-
- Òͅnà tí àwoͅn onísͅòwò POS ń gbà lu àwoͅn ènìyàn ní jìbìtì rèé – Onísͅòwò POS sͅàlàyé
Nipasẹ molumọọka oṣere Muyiwa Ademola lo fi bẹrẹ si ni gbayii, ti ipa to n ko lati da ẹrin pa oṣonu si tun mu u da yatọ.
Oṣere Yollywood ni Wale Akorede, to kawe gboye ni ile ẹkọ akọṣẹmọṣẹ ti ilu Ibadan.
Ko to dara pọ mọ awọn oṣere, okoowo ni Wale n ṣe, to maa n lọ si Saudi lọ ko aṣọ lati wa ta lorilẹede Naijiria.
- Òͅnà tí àwoͅn onísͅòwò POS ń gbà lu àwoͅn ènìyàn ní jìbìtì rèé – Onísͅòwò POS sͅàlàyé
- Orílẹ̀èdè Kenya àti South Africa ti kéde ìgbésẹ̀ físà ọ̀fẹ́ láàrin ara wọ́n
- U.S Midterm Elections- Buhari kí àwọn ọmọ Naijiria tó jáwé olúborí nínú ètò ìdìbò ilẹ̀ Amẹrika kú oríire
- Ẹnikẹ́ni tó ń lo pátákó alákọ̀ọ́lé "No parking" ń fi gbaga òfin ṣeré - Ọlọ́pàá Nàìjíríà
- Ṣ-é lóòtọ́ ni àwọn jàndùkú kọlu Atiku àti ikọ̀ ìpolongo rẹ̀ ní Borno-
Ọdun mẹtala lo fi ṣe owo aṣọ tita ko to wa papa kara bọ ere tiata. Lara awọn ere rẹ naa lo ti gba orukọ ori itage rẹ, Okunnu.
Ẹ o le wo ere rẹ ki gbogbo agbegbe kan dakẹ ṣuu, a fi ki ẹ rẹrin ni gbogbo ibi to ba ti farahan.
Baale ile ni Okunnu jẹ fun iyawo atawọn ọmọ rẹ.
- Funke Akindele, oníròyìn, agbẹjọrò àti òṣèré; ohun tí ẹ kò lérò nípa rẹ̀
- Tope Oladiji ní Ondo ti dèrò ilẹ̀ẹjọ lẹ́yìn tó ń dúnkookò láti ṣekúpa Bàbà rẹ pẹ̀lú àdá
- 'Nigeria Immigration Services' ṣàlàyé ìdí mẹ́rin tí wọ́n fi da òṣìṣẹ́ 8 dúró tí wọ́n si kìlọ̀ fún àwọn 18 míràn
- Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré
- I-gbákejì olórí ẹgbẹ́ Ilana Ọmọ Oodua kọ̀wé fi ipò sílẹ̀
- Tinubu fí MC Oluomo sínú ìgbìmọ̀ ìpolongo ìdìbò Ààrẹ
- Kí ló ń fa ìjà láàrin ọba Iragbiji àti Ẹ̀rọ̀ Àríkẹ́, gbajúmọ̀ Oníṣègùn ìbílẹ̀ l’Osun-
- Ọlọ́pàá fí èsì ìwádìí ikú ọmọ Davido, Ifeanyi Adeleke síta..-













