Iyabo Oko Illness: Ọmọ Iyabo Oko ní kò sí ńkankan mọ́, ló jẹ́ kí ẹbí bẹ̀bẹ̀ ìrànwọ́ lórí àìlera màmá òun

Oríṣun àwòrán, Foluke Daramola
Ọmọ Odunkanmi Kudirat ti gbogbo eniyan mọ si Iyabo Oko ti ke gbajare si gbogbo awọn ọmọ Naijiria, awọn ẹgbẹ osere TAMPAN ati awón ololufẹ iya rẹ lati dide adura ki ẹmi iya maa bọ.
O sọ eyi lasiko to n se ifọrọwerọ pẹlu BBC News Yoruba nitori iya rẹ to dubulẹ Aisan ni ile iwosan kan ni ilu Oyo.
Adebisi Aisha to jẹ ọmọ Iyabo Oko ṣalaye gbogbo nkan ti awọn ọmọ ti se lati toju iya wọn lati bi ọdun marun ṣẹyin lori itọju iya wọn.
- Kí ẹnikẹ́ni má ṣe ìwọ́de ìfẹ̀hónúhàn kankan ní orúkọ mi- Sunday Igboho
- Àwa ọmọ Iyabo Oko ló dá owó gọbọi fi gbé ìyá wa lọ sí India fún ìtọjú- Ewa, ọmọ Iyabo Oko
- 'Màmá mi, Iyabo Oko ti ní "Left Stroke" ní fọ́tò wọ́n ṣe rí bẹ́yẹn o àmọ́...'
- Sunday Igboho ránṣẹ́ tuntun nípa agbẹjọ́rò rẹ̀ ní Benin republic, Ó ní...
- Atọ́kùn egúngún, ọmọ rẹ̀ àti èèyàn méjì àtìmọ́lè lórí ẹ̀sùn ìpànìyàn ní mọ́ṣálááṣí
- Eèmọ̀ wọ̀lú, ẹni tó ń ta ọtí àti ògógóró gún Oníbárà rẹ̀ pa ní Osun!
- Lóòtọ́ ni ìyá yìí bímọ méjì fún ọmọ rẹ̀ tó ń bá sùn, ohun tí a ṣe síi rèé - Àjọ NSCDC Kwara
- Ìwọ́de Yoruba Nation lólú iléeṣẹ́ àjọ UN wáyé, bó ṣe lọ nìyí
- ''APC yóò fún Goodluck Jonathan ní ànfàní láti dupò ààrẹ lọ́dún 2023 tó bá darapọ̀ mọ́ wa''
Aisha ṣalaye pe ẹbẹ kan ti oun bẹ awọn eniyan ni lati wolẹ adura ati ṣiṣe iranwo owo fun iya oun ki o le dide lori akete aisan to wa.
Ninu ọrọ rẹ, o ni lati igba ti iya awọn ti ṣe aisan ni awọn ti gbale gbata lati lo se itọju rẹ loke okun ati pe ati asiko yii ni awọn ọmọ Iyabo oko to ti bọ sipo mọ.
O ni lootọ ebi o pa awọn sùgbọn awọn ko yọ, sibẹ apa awọn ẹbi ko ka owo ti ile iwosan n bere fun itọju iya wọ.
Bakan naa lo sọ pe itọju ko duro lati bi ọdun marun sẹyin, gbogbo igba ni awọn si n nawo fun ilera mama.
Ọmọ gbajumọ oṣere naa to ni ẹni ọdun mẹrindinlaadọrin ni mama fi kun un pe oun dupẹ lọwọ gbogbo awọn to ti dide iranwọ sugbọn sibẹ awọ ko tii ka oju ilu iye owo ti awọn nilo fun itọju.
Lasiko ifọrọwerọ naa, ni gbajugbaja osere tiata to maa n gbe ọrọ awọn arugbo inu ẹgbẹ jade Foluke Daramola- Salako pẹlu ṣalaye awọn nkan ti awọn ọmọ ẹgbẹ ti ṣe ati ipa ribiribi ti oun pẹlu n ko lori ọrọ Iyabo Oko.
- Wo ọ̀nà méje tí o lè fi dáàbò bò ọmọ rẹ níbàyìí tí iléẹ̀kọ́ ti bẹ̀rẹ̀ padà
- Eèmọ̀ wọ̀lú, ẹni tó ń ta ọtí àti ògógóró gún Oníbárà rẹ̀ pa ní Osun!
- Àwa ọmọ Iyabo Oko ló dá owó gọbọi fi gbé ìyá wa lọ sí India fún ìtọjú- Ewa, ọmọ Iyabo Oko
- Atọ́kùn egúngún, ọmọ rẹ̀ àti èèyàn méjì dèrò àtìmọ́lè lórí ẹ̀sùn ìpànìyàn ní mọ́ṣálááṣí
- Lóòtọ́ ni ìyá yìí bímọ méjì fún ọmọ rẹ̀ tó ń bá sùn, ohun tí a ṣe síi rèé - Àjọ NSCDC Kwara
Foluke Daramola ṣalaye pe ẹgbẹ n gbiyanju ipa ti wọn le sa lati ri daju pe awọn ọmọ ẹgbẹ gbe igbe aye to dara, sugbọn o ṣeni laanu pe, awọn igbese tuntun yii ṣẹṣẹ n bẹrẹ ni ti ko si kan awọn to ti dagba ninu ẹgbẹ.
Gbajugbaja Osere fi kun un pe ọmọ mama gan an lo pe oun pe ara mama ko ya o si lagbara gidi, nitori naa awọn nilo iranwọ fun wọn.
O ṣalaye pe ilẹ to mọ loni, awọn ti rí owo to ti fẹẹ to miliọnu meji naira, sugbọn iye ti wọn nilo gan ju miliọnu marun Naira lọ.
Bakan naa lo dupe pupọ lọwọ awọn Naijiria fun awọn nkan ti wọn se nitori pe ẹlomiran tilẹ fi ọgọ naira ransẹ, eyi si fi han pe awọn eniyan nifẹ mama naa.
- Àwọn jàndùkú jí Emir Bungudu gbé, wọ́n pa ọlọ́pàá lọ́nà mọ́rosẹ̀ Abuja sí Kaduna
- Ẹ̀yin oníṣègùn ìbílẹ̀, ẹ bá wa ṣe àwárí oògùn àjákálẹ̀ àrùn covid-19- Ìjọba Naijiria
- Iléeṣẹ́ ìjọba, ẹ yé ra ọkọ̀ tòkunbọ̀ fàyàwọ́ mọ́- Ajọ Customs kìlọ̀
- Nkechi Blessing ò lè fẹ̀sùn ibálòpọ̀ láti gba "role" kàn mí láyé! Tó bá dán an wo... - Damola Olatunji
- Ọkùnrin tó lẹ ''Super Glue'' mọ́ ǹkan ọkùnrin rẹ̀ láti rọ́pò ''condom'' ti dèrò ọ̀run
- Wo iye ìgbà tí bàálù ìjagun ti já tó sì ṣekú pa àwọn ènìyàn ní Nàìjíríà
















