Yollywood,: Olumide Olajide Òṣèré tíátà Yorùbá míràn tún kó sí gbaga ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn lílu jìbìtì

Oríṣun àwòrán, @Others
Ọwọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ ti tẹ oṣere tiata Yoruba kan ti orukọ rẹ n jẹ Olumide Olajide fun ẹsun fifi ayederu alaati atẹjiṣẹ isanwo fi lu awọn ọlọja ni jibiti ni ilu Ibadan.
Oṣere tiata naa wa lara awọn ti wọn fi oju wọn han f'ayeri lolu ileeṣẹ ọlọpaa yo wa lagbegbe Ẹlẹyẹle ni ilu Ibadan.
Oun ati akẹkọọ HND ninu imọ ẹko karakata, Purchasing and Supply kan ti orukọ rẹ n jẹ Wemimo Adeyanju ni awọn ọlọpaa patẹ wọn sita faye ri bi ẹni patẹ atarodo.
- Kí ló mú Yomi Fabiyi àti Iyabo Ojo máa sá aṣọ ìdọ̀tí ara wọn síta?
- Iyabo Ojo pé Yomi Fabiyi lẹ́jọ́, ìdí abájọ rèé
- Wo bí ìwọ́de Yomi Fabiyi nítorí ọ̀rọ̀ Baba Ijẹsha to wa ni àhámọ̀ ọlapàá ṣe n lọ nílùú Eko
- Ṣé èdì tàbí àsàsí leè sọ èèyàn di "Paedophile" tí kiní abẹ́ rẹ̀ kò ní gbé bì kan? - Elebuibon sọ̀rọ̀
- Ọmọdé méje àti olùkọ́ kan jẹ́ Ọlọrun nípè lẹ́yìn tí agbébọn ẹni ọdún 19 ṣíná ìbọn bolẹ̀ nílé ẹ̀kọ́ wọn
- Kàyèéfì! Wo ìdí tí àlùfáà ìjọ Aguda fi ń kó ère ìṣẹ̀nbáyé pamọ́?
- Ààwẹ̀ Ramadan ṣì tẹ̀síwájú dí Ọjọ́ọ̀rú, a kò tíì rí òṣùpá- Supreme Council (NSCIA)
- Ẹni tó bá ní láàkàyè, a mọ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn, àwà ti kọ lẹ́tà, èsì t'Ọ́lọ́pàá sì fún wa rèé - Yomi Fabiyi
- Àwọn ọmọ Naijiria yóò rí akitiyan ìjọba láti yanjú ètò àbò tó mẹ́hẹ láìpẹ́ - Lai Mohammed
- A ti fòfin de dída màálù ní gbangba káàkiri ilẹ̀ Yorùbá, Ibò àti ìhà Gúúsù Gúúsù - Àwọn gómìnà yarí
- Ẹ ò lè rí Covid-19 nínú ìjọ mi, ẹ má fi abẹ́rẹ́ rẹ̀ lọ̀ mí - Oyedepo
- Ìnú ìpayà, ìbẹ̀rú ní a wà nítorí a kò tíì gburò Pásítọ̀ Ìjọ Deeper Life tí wọ́n jígbẹ lọ ni ìlú Akure- Ẹbí
Agbegbe Apẹtẹ ni ilu Ibadan ni ọwọ ti baa.
Gẹgẹ bi osere tiata naa ṣe sọ, o ni oun maa n bere akanti ifowopamọ awọn ọlọja naa ẹyin ti oun ba ra ọja lọwọ wọn tan lati lee fi ayederu alaati ranṣẹ siwọn gẹgẹ bi ẹri pe oun ti sanwo.
Gẹgẹ bi Olajide ṣe sọ, alaati naa yoo farahan loju foonu awọn ọlọja naa gẹgẹ bi eyi to jẹ ojulowo lati banki wọn.
O ni, " igba mẹta pere ni mo se ki ọwọ ọlọpaa to tẹ mi."
Arabinrin kan to da a mọ nipa aworan ori oju opo WhatsApp rẹ lo kebosi sita ti ọlọpaa fi gbe e.
- 30 nínú 40 àwọn tí wọ́n jígbé nínú Mọ́ṣáláṣí lásìkò Tahajjud ní Katsina ti gba ìtúsílẹ̀
- Orílẹ̀-ède UK ti fi kún iye òfin tó de àwọn arìnrìàjò wọn tó fẹ́ wá sí Nàìjíríà nítorí…
- Ènìyàn 49 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdí ààrùn Coronavirus ní Naijiria
- Ìjọba dá òfin kónlé-ó-gbélé lórí àjàkálẹ̀ àrùn covid-19 padà
- Ṣé ẹ rántí àwọn ìkọlù tó ti wáyé ní ilé ìjọba rí? Àwọn rèé
- Bó ṣe nípasẹ̀ ọkada ni tàbí ọkọ̀ ojú omi tàbí láti inú ihò ilẹ̀, ẹ wá ọ̀nà láti fi Naijiria sílẹ̀- Pasitọ Paul Adefarasin
- Ikú kò m'ọmọdé, kò màgbà, ẹ gbàdúrà fún ìdílé mi àti aya pẹ̀lú ọmọ olóògbé- Pásítọ̀ Adeboye














