Ekiti Stolen Items: Kíní Ọlọ́pàá, mẹ̀kòó ṣe tí wọ́n fi rí ẹ̀wọ̀n gbére he ní Ekiti?

Igbakeji Kọmisọnna, Okubo Aboye ati mẹkoo rẹ ni wọn ti ran lọ si ẹwọn gbere, lẹyin ti o gba ọkọ ti wọn ji lọwọ awọn ajinigbe.
Aboye to jẹ ẹni ọdun mẹtadinlọgọta naa ni ileẹjọ giga nipinlẹ Ado-Ekiti.
Awọn meje miran ni Solomon Ayodele Obamoyegun 39, Femi Omiawe 40, Damilola Obamoyegun 20, Bose Sade Ajayi 30, George Lucky 35, Chukwuma Nnamani 22, ati Sunday Ogunleye 45 naa ni wọn ri ẹwọn ọdun marun un hẹ fun ẹsun ajinigbe.
- Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
- Fulani kìí ṣe ajínigbé! Akeredolu kò ní ká pòórá nínú igbó ìjọba l'Ondo, ohun tí Gómìnà sọ rèé...- Miyetti Allah
- Ìjọba àpapọ̀ gbé ₦10b kalẹ̀ fún ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 alábẹ́lé
- Tírélà agbépo bẹntírò gbiná nílùú Abeokuta, ọkọ̀ mérin jóná ráúráú
Awọn ọlọpaa to ṣe iwadii ijinigbe naa ni wọn ri ọkọ ti wọn jigbe naa ni ile igbe ACP Akubo Aboye, to si jẹwọ pe oun ra ọkọ Hilux van naa lọwọ ẹni to n tun ọkọ rẹ ṣe, ti wọn gba lọwọ awọn ajinigbe.
Adajọ John Adeyeye lasiko to n dajọ ni awọn mejeeji ni wọn jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn, nitori naa ni wọn si n ran wọn lọ si ẹwọn gbere.
Adajọ Adeyeye ni awọn mẹsan naa jẹbi ẹsun ijinigbe, ti wọn si bere owo ẹmi lọwọ wọn.
- Seyi Makinde pàṣẹ fún àwọn ọlọ́pàá láti wádìí Sunday Igboho lórí gbèǹdéke tó fún àwọn Fulani
- Báwo ni èròjà Fáítámì D ṣe ń dáàbò bo àgọ́ ara wa?
- Ẹ wo ohun tí Seriki Fulani sọ fún gómìnà Makinde nípa Sunday Igboho
- Iyaafin Fọlakẹ Arẹmu, Orisabunmi ti wọ káà ílẹ̀ sún
- Àwọn agbébọn ti jí àwọn arìnrìnàjò gbé ní ìpínlẹ̀ Osun!
- Coronavirus tún ṣekúpa èèyàn mẹ́rìnlá lọ́jọ́ Ajé, ẹni 1,617 míì tún kó
O fikun wi pe ọrọ ijinigbe Naijiria ti peleke si, ti ko si pin si ipinlẹ Ekiti nikan.
Bakan naa ni adajọ fikun wi pe awọn n ṣiṣẹ awọn bi iṣẹ ni wọn ṣe ṣedajọ awọn to jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn.

















