Lagos City Marathon: Ipò wo ni Gómìnà Sanwo-Olu gbà?

David Barmasai ati Gomina babajide Sanwo-Olu

Oríṣun àwòrán, Twitter/Lagos State Govt.

Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 1

Ọmọ orilẹede Kenya, David Barmasai lo gba ami ẹyẹ ipo kinni ninu ere eje-gigun ti ilu Eko ti ọdun 2020.

Barmasai pari ere to le ni kilomita mejilelogoji laarin wakati meji ati iṣẹju mẹwaa.

Skip X post, 1
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 1

Ẹbun owo to le ni miliọnu mejidinlogun naira ni Barmasai yoo mu re 'le fun ipo kinni to gba ninu ere ọhun.

Ọna ara ọtọ ni Barmasai ọmọ ilẹ Kenya gba jawe olubori ninu ere eje-gigun ọhun.

Ẹwẹ, Gomina Babajide Sanwo-Olu naa wa lara awọn to kopa ninu ere eje-gigun naa to waye niluu Eko lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹjọ oṣu keji ọdun 2020.

Ninu isọri tawọn obinrin, Sharon Cherop ti oun naa jẹ ọmọ bibi ilẹ Kenya lo jawe olubori.

Skip X post, 2
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 2

Iye owo kan naa ni ọkunrin ọkunrin ati obinrin to jawe olubori ninu ere eje-gigun naa jọ gba.

Eyi ni igba karun un ti ere eje-gigun yii yoo waye niluu Eko lẹyin ti alakọkọ iru rẹ waye lọdun 2016.