Sunday Igboho released: Ìdọ̀bálẹ̀ gbalaja ní Igboho wà tó ń dúpẹ́ pé mo mú ìlérí mi ṣẹ- Oloye Banji Akintoye

Oríṣun àwòrán, Others
Ojogbon Banji Akintoye alaga Ilana Omo Oodua naa ti sọ̀rọ̀soke lori itusile Oloye Sunday Igboho
Bẹ́ẹ̀ iriri kọ́ja ẹgbẹ́ abewu ni awọn agba n sọ nilẹ̀ Yoruba.
Ninu ọrọ Oloye Banji Akintoye, o kin ọrọ ti amofin Falọla to jẹ ọkan lara awọn agbẹjọro Oloye Adeyemo leyin.
O ni awọn ẹ̀kọ́ ti ọmọ ẹgbẹ́ Ilana Omo Oodua ti kọ́ losu mẹ́fa sẹ́yin ti kọ́ wa pelu Sunday Igboho ni ẹ̀kọ́ to pọ̀.
Ati pe ọ̀pọ̀ alangba lo danu delẹ̀, a ko mọ́ eyi ti inu n run ni awọn agba n sọ.
O ni pe kii ṣe nitori ilera rẹ ni wọn tori rẹ tu u silẹ bikoṣe pe awọn ijọba ilẹ Benin ti rii pe ko lẹṣẹ lọrun tako orilẹede wọn.
- Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington
- Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni
- 'Gbogbo ẹ̀yà ara Bamise Ayanwole ló pé nígbà tí mo rí òkú rẹ̀'
- A ti rí ilé ti à ń lọ lọ́ọ̀kán báyìí díẹ̀ ló kù - Ọ̀jọ̀gbọ́n Banji Akintoye lásíkò àjọyọ̀ ìtúsílẹ̀ Sunday Igboho
- Ademola Adeleke ní igun kíni PDP ní Osogbo fà kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọmọ oyè láti díje dupò gómìnà Osun
- Timothy Adegoke: Ìyàwó Timothy Adegoke jẹ́rìí nípa ọkọ rẹ̀ nílé ẹjọ́, gbọ́ nípa ìjà tó jà fún ọkọ̀ rẹ̀
- Ademola Adeleke ní igun kíni PDP ní Osogbo fà kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọmọ oyè láti díje dupò gómìnà Osun
- Ọkùnrin àkọ́kọ́ tó ṣàṣeyọrí lílo ọkàn ẹlẹ́dẹ̀ láti mi ti padà kú o!
Kini Ojogbon Banji Akintoye tun so?
Baba Akintoye ṣalaye siwaju sii pe itusilẹ Sunday Igboho ti tubọ fi imọlẹ han si ibi ti ọna ọmọ iran Oodua yoo gba.
Olori ẹgbẹ ilana Ọmọ Oodua pẹlu ṣalaye pe iriri pọ laarin oṣu mẹfa ti Sunday Igboho lo ni ahamọ orilẹede benin Republic.
"A ti rí ilé ti à ń lọ lọ́ọ̀kán báyìí díẹ̀ ló kù".
A ti rí ilé ti à ń lọ lọ́ọ̀kán báyìí díẹ̀ ló kù - Ọ̀jọ̀gbọ́n Banji Akintoye lásíkò àjọyọ̀ ìtúsílẹ̀ Sunday Igboho
O ni bi ilakaka ṣe n lọ lati tu Sunday Igboho silẹ ni ahamọ to wa ni awọn eeyan kan kaakiri agbaye pẹlu n lo orukọ ajafun idasilẹ orilẹede Yoruba naa lati pa owo si apo ara wọn.

Oríṣun àwòrán, others
Ọjọgbọn Akintoye ni orukọ rere ati iyi ti awọn agbaagba ilẹ Yoruba kan ni ni wọn lo lati fi ṣeto itusilẹ rẹ lorilẹede Benin republic.
"Awọn eeyan kan n sọ pe ara rẹ ko le, irọ patapata ni, alaafia lo wa."
O ni jijade ti Sunday Igboho jade bayii lẹwọn, idọbalẹ gbalaja lo mu to fi ọrọ sẹnu to si dupẹ fun aduroti oun atawọn agbaagba Yoruba yoku.
Igboho n pe: "Baba mi, O dẹ duro naa lati iye ọjọ́ yii.
O sọ pe oo ni kuro ni ilu yii titi di igba ti wọn ba tu mi silẹ.
Ẹ o dẹ lọ naa lati igba yii wa."
Agbẹjọro fun Sunday Igboho ilu Bẹnin Republic, Amofin Falola
"Ko si ṣẹkẹṣẹkẹ idiwọ kankan mọ fun eekan aṣiwaju ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho lorilẹede Benin Republic".
- 'Gbogbo ẹ̀yà ara Bamise Ayanwole ló pé nígbà tí mo rí òkú rẹ̀'
- Wo àwọn ìgbésẹ̀ tí Sunday Igboho gbé, tó fi di ọ̀tá ìjọba
- Sunday Igboho kò sì lè kúrò ní Benin Republic, sùgbọ́n ó tí kúrò ní àhámọ́ lọ gba ìtọ̀jú nílé ìwòsàn níbẹ̀- Agbẹjọ́rò Sunday Igboho
- Wọ́n ti rí òkú obìnrin ẹni ọdún 22 tó dàwátì nínú ọkọ̀ BRT l'Eko
- Ọkọ̀ tó rìn gba "one way" gbá ọmọ ìyá mẹ́rin lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo l'Eko, ọ̀kan kú
- Odindi ọdún mẹ́ta ni ọkọ mi ti ń fipá bá ìbátan mi ọmọ òrukàn ọdún mọ́kànlá lò pọ̀
Agbẹjọro fun Sunday Igboho ilu Bẹnin Republic, Amofin Falola lo sọ bẹẹ fun awọn akọroyin lọjọ Iṣẹgun.
Amofin Falọla ni lootọ o ṣi wa labẹ abo ijba lorilẹede Benin, ṣugbọn kii ṣe nitori ẹṣẹ kankan bikoṣe nitori a ti daabo bo o titi di igba ti yoo fi fi orilẹede naa silẹ lọ silẹ okeere.
- Timothy Adegoke: Raheem Adedoyin ní káwọn òṣìṣẹ́ Hòtẹ́ẹ̀lì òun fi Bíbélì búra pé wọ́n ò ní tú àṣírí
- Iléẹjọ́ yọ gómìnà ìpínlẹ̀ Ebonyi, igbákejì rẹ̀ nípò
- Wo àwọn ìgbésẹ̀ tí Sunday Igboho gbé, tó fi di ọ̀tá ìjọba
- Sunday Igboho kò sì lè kúrò ní Benin Republic, sùgbọ́n ó tí kúrò ní àhámọ́ lọ gba ìtọ̀jú nílé ìwòsàn níbẹ̀- Agbẹjọ́rò Sunday Igboho
- Àsìkò ti tó fún wa láti gba ìpínlẹ̀ Ọṣun padà lẹ́yìn ọdún kejìlá ti a tí ń se ẹgbẹ́ alátakò- Alága PDP Ọṣun
Amofin Falọla, ọkan lara awọn agbẹjọro Igboho lorilẹede Benin, ṣalaye pe kii ṣe itusilẹ lati lo gba itọju ilera ni won fun un.
O ni bikoṣe itusilẹ patapata lẹyin ti ijọba orilẹede naa rii daju pe ko ṣẹ ẹṣẹ kankan nibẹ ko si si idi kan fun wọn lati ṣi maa fi si ahamọ.

"Ko lee pada lọ si ilu Naijiria to ti wa lọwọ yii, yoo ṣi maa wa nilu Benin naa titi ti yoo fi tẹsiwaju lọ si ilẹ okeere, iyẹn orilẹede Germany to fẹ lọ."

















