EFCC mú ọmọ Yahoo tó fẹ́ fi Bitcoin ra ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí iye rẹ̀ tó 44 mílíọ́nù

Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Ileeṣẹ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ni Naijiria, EFCC, ẹka ti ipinlẹ Eko ti kede pe ọwọ awọn ti tẹ afurasi ọmọ Yahoo kan to gbiyanju lati ra ọkọ ayọkẹle SUV ti iye rẹ to miliọnu mẹrinlelogoji pẹlu Bitcoin.
EFCC fẹsun kan afurasi naa, Tobiloba Aramide Ogundiyan pe o yi owo to ri nidi iṣẹ jibiti pada si owo Bitcoin.
Oṣiṣẹ EFCC kan to ba awọn akọroyin sọrọ ni "Ọna ẹburu lo gba ri owo rẹ, o si gbiyanbju lati fi owo naa ra ọkọ ayọkẹlẹ SUV ti iye rẹ to miliọnu mẹrinlelogoji ni ṣọọbu ti wọn ti n ta ọkọ ni Lekki."
- Ẹ̀mí àìrí lé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ jáde ni ilé ẹ̀kọ́ St Claire's ní Offa
- Ọjà olówó iyebíye jóná nínú ọjà Ladipo nílùú Eko
- Kí ló bí ìsinmi tí àwọn ajìjàngbara Biafra kéde fáwọn Ibo láti ṣ'àyájọ́ Biafra
- Àwọn jàndùkú agbébọn ṣekúpa Ahmed Gulak, olùdàmọ́ràn Goodluck Jonathan
- Ó ń rúgbó bọ̀ o! Àwọn ajìjàngbara Yorùbá Nation fipá ṣí bọ́dà Idiroko, àmọ́...
Wọn fi panpẹ ofin mu afurasi ọhun pẹlu awọn meje miran lagbegbe River View Estate to wa ni Lekki fun oniruru ẹsun to jọ mọ lilu jibiti ori ayelujara.
Awọn afurasi mii ti EFCC tun mu ni Samson Alabi Afolabi; Adebayo Dolapo Olumide; Daniel Boluwatife Akinwunmi; Moses Segun; Kelechi Thankgod Felix; Adeleke Godwin Tofunmi ati Adewale Dapo Victor.
- Èmi kò pe Arinola Oloko ní 'Thug' o, ìbéèrè ni mó bèèrè lọ́wọ́ ẹ- Remi Tinubu
- Ọmọ ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn bẹ́ sódò láti bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá
- Arúmọjẹ lásán ni lọkọ-láya tí èmi àti Cute Abiola jọ́ ń ṣe tẹ́lẹ̀, ìyàwó rẹ̀ ti dé- Adeherself
- Mọ̀ síi nípa Agbẹjọ́rò àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọniyàn ni Nàìjíríà tó lọ sí ẹ̀wọ̀n nígbà 32
EFCC ni wọn ka awọn ohun ìní olowo iyebiye lọwọ wọn bii ẹrọ ilewọ, ẹrọ ayarasbiaṣa alagbeka, oriṣiriṣi ọkọ olowo iyebiye, ẹṣọ ara ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ileeṣẹ naa ni yatọ si jibiti ori ayeluja, awọn afurasi ọhun tun n lu jibiti lọna miran.
- Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Greenfield tí wọ́n jí gbé ní Kaduna gba òmìnira lẹ́yìn tí àwọn òbí wọn san "180 mílíọ́nù naira"
- Ariwo ẹkún sọ lẹ́yìn tí wọ́n ṣàwárí òkú akẹ́kọ̀ọ́ 215 nílé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ yìí
- Bí Ààrẹ Buhari bá parí sáà rẹ̀ tán ni ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria yóò mọ rírì iṣẹ́ tó ń ṣe - Ìjọba àpapọ̀
- Kàyéèfì! Ọwọ́ tẹ òkú tó ń ká àwọn èèyàn mọ́lé, to sì ń jà wọ́n lólè dúkìá









