Olamiju Alao-Akala: Mo ṣì máa ń wo fóònù mi bíì pé bàbá mi Akala fẹ́ pe mi, gbogbo ǹkan ni mo fi ṣàárò wọn
"Owo ti ọmọde ba kọkọ ri, ẹpa ni yoo fi ra jẹ, lootọ awọn ọrẹ kan wa ti yoo gba eeyan nimọran odi ti eeyan yoo si tẹle e".
BBC Yoruba ni ifọrọwerọ pẹlu ọmọ gbajugbaja oloṣelu to tun jẹ gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri, Adebayo Alao Akala.
- Láí ṣẹ̀ láí rò, wọ́n jó Ṣọ́ọ́ṣì mi pátápátá ní Sokoto, ìrírí mi rèé - Pasitọ ìjọ Celestial
- Adájọ́ 34 táa tán nílé ẹjọ́, bí wọ́n ṣe sọ àwọn afurasí tó lọ́wọ́ nínú ikú Deborah Samuel sẹ́wọ̀n rèé
- Osun 2022: Kò sí ìjà mọ́, Adeleke àti Babayemi ṣetán láti jọ ṣiṣẹ́ papọ̀
- A ò sọ pé ọmọ orílẹ̀ èdè Niger ni àwọn afurasí ta mú ní Sokoto - Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá
- Odunlade Adekola fakọyọ níbi àmì èyẹ AMVCA, ohun tí akẹgbé rẹ̀ Bukunmi sọ rèé
- Yorùbá ẹ fúnra, àwọn tó ṣekú pa Deborah fẹ́ dá ògún sílẹ̀ ni, wọn kò gbọdọ̀ lọ láì jìyà -Gani Adams
- Wo àwon ìròyìn òfégè nípa ikú Deborah Ṣamuel àti ìkọlù sí Bishop Kukah
Olamiju Akala kẹnu bọ ọpọ ọrọ lati ṣalaye irinajo oṣelu rẹ nigba ti baba rẹ wa laye, awọn idiwọ to koju, ati bo ṣe n baa yi lẹyin iku baba rẹ to jẹ bii ẹni to fẹyin ti ju nigba aye rẹ.

