Ìwé ẹ̀rí àyẹ̀wò oògùn olóró yóò di dandan fún ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ gbé'yàwò láìpẹ́- Buba Marwa NDLEA

Ajọ naa ni eyi kun ara ero tuntun ti wọn n gberolatidẹkun elo ogun oloro lorilẹede Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ogun oloro ni Naijiria, NDLEA ni laipẹ laijina gbogbo awọn to ba fẹ ṣe igbeyawo lorilẹede Naijiria ni yoo ni lati maa gba iwe aṣẹ ọ mọ lọwọ ogun oloro ki wọn to lee ṣegbeyawo.
Alaga ajọ naa, Ọgagunfẹyinti Buba Marwa lo sọ eyi di mimọ nibi ayẹyẹ kan n'ipinle Kogi.
- Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ tí adigunjalè bá kọ lẹ́tà sí yín pé àwọn fẹ́ ẹ́ wá jà yín lólè
- Mó ṣèlérí láti buwọ́lu àtúntò Naijiria, Ilé Aṣòfin o kù sí ọwọ́ yín - Ààrẹ́ Buhari
- Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo àti àwọn ẹlẹ́sìn àbáláyé bẹ̀rẹ̀ àjọṣepọ̀ láti fí opin sí ìṣoro ètò aàbò
- Àwọn lọ́balọ́ba nílẹ̀ Yoruba dalẹ̀ wa lórí àwọn ọmọ OPC mẹ́ta tí wọ́n tímólé láìṣẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Iskilu Wakili - Ẹgbẹ́ OPC
- Wo ìlànà tí ó máa tẹ̀lé láti wo èsì ìdánwò 2021 Jamb UTME rẹ lórí ayélujára àti SMS
- Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ tí adigunjalè bá kọ lẹ́tà sí yín pé àwọn fẹ́ ẹ́ wá jà yín lólè
Ọgagun Marwa ni ipinu Aarẹ Buhari lati le ogun oloro lorilẹ-ede Naijiria ko yingbin rara.
O ni idi gan niyi ti wọn fi gbe awọn etokan silẹ ninu eyiti gbogba iwe ayẹwo ogun oloro saaju Igbeyawo gẹgẹ bi I iwe ayẹwo HIV ṣe fẹ waye.
Koda o ni " Laipẹ jọjọ ẹnikẹni to ba n wa iṣẹ ijọba tabi n wa ati wọlẹ si ile ẹkọ gigaga tabi gbeyawo yoo kọkọ ni lati ṣe ayẹwo ogun oloro na."
Marwa tun salaye pe ileṣẹ NDLEA ti ri oogun oloro to le ni milionu meji kilogiraamu gba pada lọwọ awọn eeyan ni kete ti oun ti wọ iṣẹ gẹgẹ bii ọga wọn.
- Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ń ṣelédè lẹ́yìn Ajimobi, èrò wọn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀!
- Ọmọ ọdún méje ni mo ti ń digunjalè, ogun ìdílé ló fàá, afurasí ṣàlàyé l'Ondo
- Wo iléẹ̀kọ́ tí wọ́n kò ti fààyè gba akẹ́kọ̀ọ́ láti padà sọ́dọ̀ Òbí tàbí ìlú rẹ̀ lẹ́yìn tó bá parí
- Èèyàn kan ti kú, 99 di àwátì lẹ́yìn tí ilé alájà méjìlá wó lulẹ̀ l'óru
- Iyabo Ojo, mẹ́nu kúrò lórí ọ̀rọ̀ Baba Ijesha ní báyìí tí ọ̀rọ̀ ti dé iwájú mi - Adájọ́ Toyin Taiwo










