National Grid collapse: Òpó iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì daṣẹ́rú, ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà wà lókùnkùn

Oríṣun àwòrán, Others
Opo apapọ ina ẹlẹntiriki lorilẹ-ede Naijiria ti a mọ si National grids ti dẹnukọlẹ eti si ti sọ awọn apakan orilẹ-ede Naijiria sinu okunkun birimi.
Ileeṣẹ to n pin ina ẹlẹntiriki lorilẹede Naijiria, TCN ṣalaye irinṣẹ ipinna lorilẹ-ede Naijiria lo ṣa dede dẹnukọlẹ ni nnkan bii agogo mọkanla kọja iṣẹju kan owurọ Ọjọru.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post
Awọn ilẹsẹ ina bii EkoWlectric, Ikeja Electric ati Kaduna Electric ni tiwọn ti jẹwọ pe kini naa ti ba awọn ati pe awọn ko ri ina fun araalu bayii.
- Àjọ́ CAN pàṣẹ ètò àdúrà ọlọ́jọ́ mẹ́tà fún Naijiria ní May 28 sí 30, ẹ wo kókó àdúrá...
- Kàyèéfì! Wo ìdí tí àlùfáà ìjọ Aguda fi ń kó ère ìṣẹ̀nbáyé pamọ́?
- Obìnrin ẹni ọdún 67 di àwátì lásìkò tó ń lọ sí ìṣọ́ òru
- Lẹ́yìn ìwọ́de Yomi Fabiyi, ọlọ́pàá sọ ìdí tí wọ́n kò fi gba béélì Baba Ijẹsha, àti ìgbà tó ṣe é ṣe kí wọ́n ó fi sílẹ̀
- Ohun tí mo fẹ́ ṣe fún ẹbí ẹ̀gbọ́n mí, Dare Adeboye rè é ... -Leke Adeboye
- Iyabo Ojo pé Yomi Fabiyi lẹ́jọ́, ìdí abájọ rèé
Ajọ TCN ni lọgan lawọn bẹrẹ atunṣe ati irapada awọn irinṣẹ ipinna to dẹnu kọlẹ naa ni nnkan bii agogo mọkanla kọja iṣẹju mọkandinlọgbọn owurọ.
Ajọ naa ni bi a ṣe n sọrọ yii, ina ọba ti n pada sawọn agbegbe kan kaakiri ni Naijiria.
Ninu iforowerọ pẹlu BBC, ajọ amunawa ilu Ikeja, Ikeja Electric ni ọda ina lati pin fun araalu da awọn ni nnkan bii agogomọkanla aarọ ki wọn to rii gba pada ni nnkan bii agogo kan ọsan ku iṣẹ kẹrindinlogun.
Loju opo Twitter rẹ, ajọ amunawa ilu Kaduna kọọ wi pe:
O ni" "Ẹyin onibara wa, o ba wa lọkan jẹ pupọ lati sọ fun yin pe aisi ina ọba to n waye lọwọ yii l'awọnipinlẹ to wa labẹ isakoso wa bii Sokoto,kaduna, Kebbi, Zamfara.

Oríṣun àwòrán, others
Ko ṣẹyin bi oju opo ipese ina apapọ orile-ede Naijiria.
Laipẹ laijinna ti iṣẹ ba ti pari lori atunṣe naa ni ina ọba yoo maa de ni awọn agbegbe bi o ti yẹ.
- Àwọn ọmọ Naijiria yóò rí akitiyan ìjọba láti yanjú ètò àbò tó mẹ́hẹ láìpẹ́ - Lai Mohammed
- Ẹni tó bá ní láàkàyè, a mọ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn, àwà ti kọ lẹ́tà, èsì t'Ọ́lọ́pàá sì fún wa rèé - Yomi Fabiyi
- Ọmọdé méje àti olùkọ́ kan jẹ́ Ọlọrun nípè lẹ́yìn tí agbébọn ẹni ọdún 19 ṣíná ìbọn bolẹ̀ nílé ẹ̀kọ́ wọn
- Òṣèré tíátà Yorùbá míràn tún kó sí gbaga ọlọ́pàá
- Eid al-Fitr: Wo àwọn ohun tó yẹ ki o ṣe sáájú ìrun Yidi fún ọdún ìtúnu ààwẹ̀
- Ogójì èèyàn ti pàdánù ẹ̀mí wọn nítorí ìjà tó ń wáyé láàrín Israel àti Palestine ní Lod
- Wo bí ìwọ́de Yomi Fabiyi nítorí ọ̀rọ̀ Baba Ijẹsha to wa ni àhámọ̀ ọlapàá ṣe n lọ nílùú Eko















