BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ètò Ìdájọ́
Ayédèrú òṣìṣẹ́ aṣọ́bodè lu Soun Ogbomoso ní jìbìtì N39.5m, ọ̀rọ̀ di tilé ẹjọ́
27 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ìjà àgbà méjì bẹ̀rẹ̀ láàrin Abubakar Malami àti EFCC, bó ṣe ń jẹ́jọ́ ẹ̀sùn kíkó dúkìá tó tó N212bn lọ́nà èrú jọ
25 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Ìtàn rèé nípa bí ikú Bola Ige ṣe ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọdún 24 tó jáde láyé, láì mú ẹni tó pa á
23 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Wasiu Ayinde kéde pé òun kò du ipò Awujalẹ mọ́ lẹ́yìn tó lulẹ̀ lórí ẹjọ tó pé tako ìgbésẹ̀ yíyan Awujale tuntun
23 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
5:37
Fídíò,
"Àwọn dókítà yọ kíndìnrín mi láì sọ fún mi, oṣù kẹta rèé tí mi ò lè tọ̀, ṣe ni inú mi ń wú tí mo bá jẹun kékeré"
, Duration 5,37
23 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
8:00
Fídíò,
"Isẹ́ agbálẹ̀-ọjà ni mo fi bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ nijọba ìbílẹ̀, mo jìyà, dá àjọ, gba owóyàá, pa ebi mọ́nú fún ọ̀pọ̀ ọdún, kí n tó le kọ ilé àmọ́ ijọba Oyo wó o lulẹ̀ torí ọ̀nà Circular"
, Duration 8,00
12 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Princess gbé ìkìlọ̀ síta lẹ́yìn ìtúsílẹ̀ Baba Ijesha lọ́gba ẹ̀wọ̀n
15 Bélú 2025
EFCC dá ilé, ọkọ̀ àti dúkìá míì padà fún ẹni tí Abọrẹ̀ kan lù ní jìbìtì n‘Ibadan èyí tó lé ní ₦200m
30 Ọ̀wàrà 2025
Tinubu sọ ìdáríjì Maryam Sanda tó pa ọkọ rẹ̀ di ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá, yọ ìdáríjìn fáwọn èèyàn tí ẹ̀ṣẹ̀ wọn le gan
30 Ọ̀wàrà 2025
3:47
Fídíò,
"Mo ní ìjàmbá ọkọ̀ lẹ́nu iṣẹ́ ọlọ́pàá, n kò le rìn mọ́, mo ná N25m ẹ̀yáwó báńkì lórí àárẹ̀, iléeṣẹ́ ọlọ́pàá kò yà sí mi, ìran mi kò lè ṣe iṣẹ́ ọlọ́pàá mọ́"
, Duration 3,47
28 Ọ̀wàrà 2025
Ẹ̀sùn tí Kanu ń jẹ́jọ́ lé lórí kò ye, mo rọ̀ ọ́ láti kan sáwọn àgbà agbẹjọ́rò fún àlàyé kó tó pẹ́ jù - Adájọ́
28 Ọ̀wàrà 2025
Iléẹjọ́ ti dá wa láre, mó ń padà sí gáréèjì bíi alága NURTW l‘Oyo lẹ́yìn ìdádúró ọ̀dún mẹ́fà àmọ́ a kò ní fa wàhálà - Ejiogbe
27 Ọ̀wàrà 2025
Ara Nnamdi Kanu le láti máa jẹ́jọ́ - Àbọ̀ ìwádìí àwọn dókítà sọ
17 Ọ̀wàrà 2025
Natasha Akpoti lulẹ̀ lórí ẹjọ́ tó pé tako olórí ilé aṣòfin àgbà nípa oṣù mẹ́fà tó fi ní kó lọ rọọ́kún nílé
4 Ọ̀wàrà 2025
Èèyàn meji dèrò ẹ̀wọ̀n fún ẹ̀sùn pé wọ́n fẹ́ẹ́ fi ẹyẹ àjẹ́ pa ààrẹ
16 Owewe 2025
Ìdí rèé tí ilé ẹjọ́ ṣe kọ láti gba béèlì afurasí márùn-ún tó kọlu ṣọ́ọ̀ṣì Owo èyí tó gbẹ̀mí èèyàn ogójì
11 Owewe 2025
3:39
Fídíò,
"Òpó iná IKEDC ló wó lù mí lọ́dún méje sẹ́yìn, ń kò le rìn tàbí dá jẹun, ọ̀rá ni mo fi ń tọ̀, owó ti tán, mo ná N3m láti wo egbò ara mi"
, Duration 3,39
8 Owewe 2025
Wo Ọba kan nílẹ̀ Yorùbá tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n yẹgi fún torí ó jí ọmọ ọdún kan láti fi ṣe ètùtù
8 Owewe 2025
Ìyàwó Mohbad ní òun ṣetán láti ṣàyẹ̀wò DNA fún Liam, bàbá Mohbad ní ìlú òyìnbó lòun ti fẹ́ kí wọ́n ṣe é
3 Owewe 2025
Ààrẹ yọ adájọ́ àgbà nípò lórí ẹ̀sùn àṣìlò ipò tí àráàlú kan fi kàn án
2 Owewe 2025
Ṣé ìjọba Osun lè pe ìjọba àpapọ̀ lẹ́jọ́ lórí owó ìjọba ìbílẹ̀ bí?
27 Ògún 2025
"Àwọn Fijilanté tó já mi sí ìhòòhò, halẹ̀ mọ́ mi pé àwọn yóò yìnbọn pa mi, ju òkú mi sínú igbó"
23 Ògún 2025
Baba Mohbad sọ̀rọ̀ lórí fídíò tí Naira Marley ṣe nípa ikú ọmọ rẹ̀, ó sọ ìgbésẹ̀ tó kàn
22 Ògún 2025
Ṣé ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí ni APC àti PDP gẹ́gẹ́ bíi ọ̀rọ̀ ilé ẹjọ́ Canada?
15 Ògún 2025
Page
1
nínú
31
1
2
3
4
5
6
7
31
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology