Ta ni Rasheed Balogun, alákòso ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Shooting Stars to dolóògbé?

Oríṣun àwòrán, @Rasheed Balogun
Lale ana ni Balogun Rasheed jade laye!
Rasheed Balogun to jẹ alakoso ẹgbẹ agbabọọlu 'Shooting Stars' yii lo re ibi agba n re ni ogunjọ ọsu kinni, ọdun 2022 yii.
Lati igba ti o ti doloogbe ni ọpọ ọmọ Naijiria ti n beere nipa oloogbe naa.
Won kede iku rẹ lẹyin aisan ranpẹ ko to o doloogbe nile iwosan ni Ibadan
Loni, ọjọ kọkanlelogun, oṣu kinni, ọdun 2022 ni eto isinku rẹ a waye
- Wo bí ọlọ́pàá ṣe rí òkú ọmọ ọdún márùn-ún tí wọ́n ní olùkọ́ rẹ̀ jígbé
- Oníbárà tí a bá mú lẹ́sẹ̀ títì yóò sùn ẹ̀wọ̀n- ìjọba Ìpínlẹ̀ Kwara
- Èèyàn 17 kú, 60 farapa níbí ìbúgbàmù kan tó wáyé ní ìlú Bogoso
- Níbo ni ìbọn 178, 549 wọlẹ̀ sí níléeṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà?
- Yíyọ ìkúnpá orí epo bẹntiróòlù lásìkò yìí yóò fi kún ìṣẹ́ àti òṣì \eèyàn Nàìjíríà ni- Abdulsalami

Oríṣun àwòrán, Others
Ta ni Rasheed Balogun?
Rasheed Balogun jẹ ẹni ọdun mejilelọgọta.
O gba igbega si Nigeria Professional Football League lọdun karun un lẹyin ti wọn kuro ni Nigeria National League.

Lọdun 2014 ni ijọba ipinlẹ Oyo yan Rasheed Balogun gẹgẹ bii alakoso ẹgbẹ agbabọọlu Shooting Stars.
Bakan naa ni Balogun ṣiṣẹ pẹlu ikọ agbabọọlu Dolphins ni Port Harcourt ni ipinle Rivers.

Rasheed sise bi alakoso Dolphin ki o to lọ si ọdọ awọn ikọ Sunshine Stars nibi to ti jẹ alakoso ikọ naa.
O ṣe igbeyawo, o si bimọ.

Iroyin naa ni o saisan fun igba die ki ọlọjọ to de.
Oni ni wọn sín Oloogbe Rasheed Balogun ni ile rẹ to wa ni Mowe ni ipinle Ogun.
Rasheed Balogun tó jẹ́ alákóso ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Shooting Stars ní Ibadan ti jáde láyé
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajo yajo ni pe alakoso ikọ agbabọọlu Shooting Stars to fi Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni Guusu Iwo Oorun Naijiria ṣe ibujoko ti jade laye.

Ogbeni Rasheed Balogun ni wọn ni pe o ti rẹ ẹ diẹ tẹlẹ ni ọna ọfun rẹ.
- Yíyọ ìkúnpá orí epo bẹntiróòlù lásìkò yìí yóò fi kún ìṣẹ́ àti òṣì \eèyàn Nàìjíríà ni- Abdulsalami
- Wo bí ọlọ́pàá ṣe rí òkú ọmọ ọdún márùn-ún tí wọ́n ní olùkọ́ rẹ̀ jígbé
- Oníbárà tí a bá mú lẹ́sẹ̀ títì yóò sùn ẹ̀wọ̀n- ìjọba Ìpínlẹ̀ Kwara
- Èèyàn 17 kú, 60 farapa níbí ìbúgbàmù kan tó wáyé ní ìlú Bogoso
- Níbo ni ìbọn 178, 549 wọlẹ̀ sí níléeṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà?
Okan ninu awọn akọnimọọgba ẹgbẹ naa lo fidi ẹ mulẹ pe iku ti mu Rasheed Balogun lọ.
Iroyin naa ni pe o jade laye ni ogunjọ oṣu yii.
Awọn ẹgbẹ Ibadan Football Association naa ti fidiẹ mulẹ pe wọn padanu akinkanju kan.
Won ti sun idije bọọlu to yẹ ko waye loni siwaju.
- Owó ẹjọ́ Makinde dá wàhálà sílẹ̀ láàrín àwọn adárí káńsù lásíkò Ajimobi l'Oyo
- Àwọn nǹkan mẹ́fà tó so Ààrẹ Muhammadu Buhari pọ̀ mọ́ Ìpínlẹ̀ Kaduna
- Mínísítà fí ìkìlọ síta lẹyìn tí òjò àrọ̀rọ̀dá àti àrá sán pa èèyàn 82
- Ìwádìí òótọ́: Ṣé igi àti pákó ni wọ́n tò sínú ìrẹsì gogoro tí Ààrẹ Buhari ṣe ìfilọlẹ̀ l'Abuja?














