Osun state: Èèyàn márùn ún kó sí gbaga ọlọ́pàá lórí ikú ẹ̀ni ọdún 42 kan l'Ẹ́dẹ

Oríṣun àwòrán, other
Ọwọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun ti tẹ awọn afurasi ọdaran marun un kanlori iku ẹni ọdun mejilelogoji kan ti orukọ rẹ n jẹ Wakili Ọlayiwọla ni agbegbe Arulogun ni ilu Ẹdẹ l'Ọjọbọ.
Gẹgẹ bi awn eeyan ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣe sọ, awọn janduku kan ti wọn to ọgbọn ni iye kslu ile oloogbe naa ti wọn si rọ ojo ibọn lee.
- 'Ẹ wòó kò jọọ́, èmi kò lè so nọ́mbà fóònù mi mọ́ NIN tíjọba Nàìjíríà ń gbé kiri'
- 'Nígbá tí a rí Baba Ijesha lónìí ní Panti, ohun tójú wa rí, ẹnu kò lè sọ o!'
- ICPC ń wá ọkọ ọmọ Buhari àtàwọn méjì míì lórí ṣíṣe $65,000,000 kúmọ kùmọ
- Àwọn ọlọ́pàá fojú afurasí to ṣekúpa Iniubong Umoren hàn bí ó ti wọ káà ilẹ̀ lọ
- Saudi Arabia, Iran àti Egypt wà lára orile-ede àgbáyé tó ga jùlọ láti fi ikú ṣe ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ lọ́dún 2020
Ileeṣẹ ọlọpaa, ninu atẹjade kan ti alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Yẹmisi Ọpalọla fi sita awọn eeyan meji kagbako iku ojiji lọwọ awọn janduku naa ti wọn si ti gbe oku wọn si ile igbokupamọsi.
Bakan naa ni wọn ni wọn ka awọn ohun ija oloro bi ibọn oloju kan, ibọn ṣakabula kan, ọta ibọn mẹjọ, aake, ada, ogun abẹnugọngọ ati alupupu marun.
Awọn iroyin abẹle tun fi kun un pe awọn afurasi ọdaran naa tun da ina sun ọkọ ayọkẹlẹ Toyota corola to jẹ ti ọkunrin naa.
- Àwọn Olùkọ́ Akure pegedé lórí ètò Akomolede àti Aṣa lórí BBC Yorùbá
- Ṣé lóòtọ́ọ́ ni akẹ́kọ̀ọ́bìnrin fásítì Akungba l'Ondo gbẹ̀mí ara rẹ̀?
- Ṣé ǹkan oṣù rẹ ń dà hìì hìì lẹ́yìn tóó gba abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19? Ẹ gbọ́ tuntun lẹ́nu àwọn Dókítà
- Irọ́ ni pé àwọn ajínigbé ń bèèrè fún N30m láti tú pásítọ̀ Deeper Life sílẹ̀- ọmọ pásítọ̀
- Ìjá tó ń lọ́ láàrin ilẹ̀ Israel átí Palestian kò bá wa lára mú, ó ń kọwálọ́minú- Ìjọba Naijiria










