Student commits suicide: Ṣé lóòtọ́ọ́ ni akẹ́kọ̀ọ́ fásítì Akungba gbẹ̀mí ara rẹ̀?

Oríṣun àwòrán, others
Iroyin to lu ori ayelujara ni pe akẹkọọ nipa eto oṣelu ni fasiti ipinlẹ, ni ipinlẹ Ondo to wa niluu Akungba Akoko, Feranmi Fasunle Omowunmi.
Feranmi ti nọmba igbaniwọle rẹ si ile ẹkọ naa jẹ 180503006 ni iroyin sọ pe o mu oogun peku peku lati pa ara rẹ l'Ọjọru.
Ko si ẹni to le sọ pato ohun to ṣe okunfa iku ọdọmọbinrin naa ṣugbọn awọn kan sọ pe o ṣeeṣe ki o gbẹmi ara rẹ lẹyin ti ibaṣepọ rẹ pẹlu ọrẹkunrin rẹ fori ṣanpọn.
- Ṣé ǹkan oṣù rẹ ń dà hìì hìì lẹ́yìn tóó gba abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19? Ẹ gbọ́ tuntun lẹ́nu àwọn Dókítà
- Wo bí wọ́n ṣe kírun ìtúnu àwẹ̀ Ramadan 2021 ní Makkah àti Medina ní Saudi lónìí
- Òpó iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì daṣẹ́rú, ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà wà lókùnkùn
- Wo bí wọ́n ṣe kírun ìtúnu àwẹ̀ Ramadan 2021 ní Makkah àti Medina ní Saudi lónìí
- Iyabo Ojo pé Yomi Fabiyi lẹ́jọ́, ìdí abájọ rèé
- Wo bí ìwọ́de Yomi Fabiyi nítorí ọ̀rọ̀ Baba Ijẹsha to wa ni àhámọ̀ ọlapàá ṣe n lọ nílùú Eko
- Ṣé èdì tàbí àsàsí leè sọ èèyàn di "Paedophile" tí kiní abẹ́ rẹ̀ kò ní gbé bì kan? - Elebuibon sọ̀rọ̀
- Ansoogun, akọni tó bínú wọlẹ̀ di àpáta ní Ogbomoso tó wá ń gbọ́ àdúrà lásìkò yìí
Ṣugbọn awọn ọrẹ to sun mọ ṣalaye fawọn akọroyin pe irọ nla lọrọ naa nitori awọn ko mọ ọ mọ ọkunrin kankan lati igba to ti wọle si ile ẹkọ naa.
Iroyin sọ pe awọn ọrẹ Feranmi lo ri pe o ti mu oogun ti o si n pọkaka iku ninu ile rẹ.
Lati ibẹ ni wọn ti gbe e lọ si ile iwosan fun itọju awọn eleru ti sun igi.
A gbọ wi pe awọn obi rẹ wa nile iwosan nibi ti o ti pada gbẹmi mi.
Awọn alaṣẹ ile ẹkọ naa ṣalaye pe otitọ ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ, amọ ko si ẹni to le sọ pe ohun to faa to fi pa ara rẹ gan na niyii.
Nigba ti BBC Yoruba ba ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo sọrọ, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Teo Ikoro sọ pe awọn naa ti ka nipa iṣẹlẹ ọhun lori ayelujara.
Ṣugbọn Ọgbẹni IKoro ṣalaye ko si ẹni ti o tii mu ọrọ naa wa sọdọ awọn ọlọpaa.
Ọgbẹni Ikoro ni ileeṣẹ ko le mu ẹnikẹni ti eeyan ba gba ẹmi ara rẹ.
O ni ileeṣẹ ọlọpaa le bẹrẹ iwadii ti awọn ẹbi ẹni to ba p ara ba fu ra si ẹnikan pe oun lo wa ni idi rẹ loku.
- Òṣèré tíátà Yorùbá míràn tún kó sí gbaga ọlọ́pàá
- Ogójì èèyàn ti pàdánù ẹ̀mí wọn nítorí ìjà tó ń wáyé láàrín Israel àti Palestine ní Lod
- Wo bí ìwọ́de Yomi Fabiyi nítorí ọ̀rọ̀ Baba Ijẹsha to wa ni àhámọ̀ ọlapàá ṣe n lọ nílùú Eko
- Davido sí Yomi Fabiyi: Mùmú ni ẹ́
- Ẹni tó bá ní láàkàyè, a mọ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn, àwà ti kọ lẹ́tà, èsì t'Ọ́lọ́pàá sì fún wa rèé - Yomi Fabiyi
- Ọmọdé méje àti olùkọ́ kan jẹ́ Ọlọrun nípè lẹ́yìn tí agbébọn ẹni ọdún 19 ṣíná ìbọn bolẹ̀ nílé ẹ̀kọ́ wọn














