MC Oluomo: Baba tó dàbí MC Oluomo láyé yìí kòsí, ẹni tó bá ní, ó ní ohun gbogbo- Ọmọ MC Oluọmọ

Oríṣun àwòrán, Instagram
Ọmọ MC Oluomo ti sapejuwe Baba rẹ, Musiliu Ayinde Adesanya ti inagijẹ rẹ n jẹ MC Oluomo gẹgẹ bi ẹni to mu iwuri ba oun ni gbogbo ọna.
Ni Oju opo ikansiraẹni Instagram ni o ti sọ ọrọ iwuri nipa baba rẹ.
O ni ọdun marun un ṣẹyin ni MC Oluomo pe awọn ọmọ si ijoko to si sọ iriri rẹ fun wọn nipa bi oun ṣe di ẹni ti oun da loni.
- Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
- Báwo ní Ọba Rilwan Akiolu tí ìlú Eko ṣe ní $2 million àti N17 million sí inú àfin rẹ̀?
- Wọ́n tún yìnbọn níbi àpèjẹ 'Ẹ káàbọ̀' tí wọ́n ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Zamfara lẹ́yìn àṣẹ Buhari
- Ìjà ti parí, a ti gbà láti má a gbé ounjẹ wá sí ilẹ̀ Yoruba padà'- Hausa-Fulani Ọlọ́jà
- "Sọ́jà fi ìbọn gé mi lọ́wọ́ kó lè fipá bámi lòpọ̀"
MC oluomo ni oun ti ṣe gbogbo ohun to yẹ ki oun ṣe lori wọn gẹgẹ bi baba, ti oun ko si jẹ wọn ni gbese mọ.
This article contains content provided by Instagram. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read Instagram cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of Instagram post
''Ohun ti mo jẹ yin ni eto ẹkọ, eleyii ti mo si ti fun yin gẹgẹ bi ọmọ,ti ọpọ yin si ti kẹkọ jade''
M C Oluọmọ ni: ''E lo ẹkọ yin ati fi di eniyan nla ni ẹyinwa ọla, ki e si le e daduro fun ara yin laiwo oju baba yin''
- Àwọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́bìnrin gbé ní Zamfara fẹ́ yẹ̀yẹ́ Ìjọba Buhari ni- Hadi Sirika
- Wọ́n tún yìnbọn níbi àpèjẹ 'Ẹ káàbọ̀' tí wọ́n ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Zamfara lẹ́yìn àṣẹ Buhari
- Ìjà ti parí, a ti gbà láti má a gbé ounjẹ wá sí ilẹ̀ Yoruba padà'- Hausa-Fulani Ọlọ́jà
- Báwo ní Ọba Rilwan Akiolu tí ìlú Eko ṣe ní $2 million àti N17 million sí inú àfin rẹ̀?
''Nitori mi o ni ile tabi ilẹ ti ẹ fẹjogun lati ọwọ mi, mo ti fun un yin ni ogun to yẹ fun yin''

Oríṣun àwòrán, Instagram
Inu mi dun pe mo jẹ ọmọ Adesanya, iyẹn MC Oluomo, bi o tilẹ jẹpe ọpọlọpọ eniyan lo ma n sọrọ abuku si baba mi''
''Eniyan nla ni to n gbadura, to si ni ifẹ awọn ọmọ rẹ daradara.''
''Ẹni to ba ni MC Oluomo ni baba, ni ohun gbogbo.''
O ni ohun to ba wu awọn eeyna ki wọn maa sọ laidara nipa baba oun MC Olu ọmọ
- Wo ìtàn Orunmila, Babaláwo àkọ́kọ́ àti ohun tó fi sílẹ̀ lọ níbí
- Àwọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́bìnrin gbé ní Zamfara fẹ́ yẹ̀yẹ́ Ìjọba Buhari ni- Hadi Sirika
- Wo ibi tí o ti lè fi orúkọ síìmù rẹ sílẹ̀ tàbí gba nọ́mbà tuntun tí síìmù rẹ bá sọnù
- Èèyàn 464 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà
- Nǹkan dé, Igboho ní káwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Yorùbá lọ múra ògùn jọ nítorí ohun tó ń bọ̀ lọ́nà
- Ohun tó yẹ kí ó mọ̀ nípa oríṣìíríṣìí ìlẹ̀kẹ̀ ìbàdí rè é
- Ọlọrun má jẹ́ kí a jẹ́ gbèsè lókù báyìí tí a kò kó ọjá lọ sílẹ̀ Yorùbá mọ́- Hausa Oníṣòwò

Oríṣun àwòrán, Google
Tani MC oluomo?
Musiliu Ayinde ti inagijẹ rẹ jẹ MC Oluomo ni Alaga ẹgbẹ awọn awakọ NURTW ni ipinlẹ Eko.
Ojọ Kẹrinla, Ọdun 1975 ni wọn bi MC Oluomo to si fẹ iyawo mẹrin ati ọmọ mẹsan.
Laipẹ yii ni o kọ iwe to sọ nipa igbeaye rẹ, to si pe orukọ rẹ ni iṣẹ mi fun ọmọniyan, "My Service to Humanity".
- Ẹ kó àwọn ọkọ̀ yín tó ti dẹnukọlẹ̀ kúrò lójú popo tàbí kí a gbẹ́sẹ̀lé wọn- FRSC sí àwọn awakọ̀
- Ohun tó yẹ kí ó mọ̀ nípa oríṣìíríṣìí ìlẹ̀kẹ̀ ìbàdí rè é
- Ẹ wo bí ìyàwó Pasitọ Adeboye ṣe sàpèjúwe rẹ̀
- Wo ìtàn Orunmila, Babaláwo àkọ́kọ́ àti ohun tó fi sílẹ̀ lọ níbí
- Ọlọrun má jẹ́ kí a jẹ́ gbèsè lókù báyìí tí a kò kó ọjá lọ sílẹ̀ Yorùbá mọ́- Hausa Oníṣòwò















