Orisabunmi Olasanya: Pásítọ̀ àti Alfa ń wá ṣe òògùn lọ́dọ̀ bàbá mi, ìṣẹ̀ṣe ni kìí ṣe àmúlùmálà
Ninu ẹsin mẹta to wa nilẹ Naijiria, eyiun ẹsin isẹse, Kristiẹni ati Islam, isẹse nikan lo jẹ abalaye nilẹ oruba.
Amọ ọpọ eeyan ni kii fẹ safihan ẹsin naa ni gbangba, ti wọn si ri bii ẹsin ti ko laju ati ẹsin atijọ.
O si jẹ iyalẹnu nla lati ri ọmọge to n se ẹsin yii lai fi pamọ, to n so owo ẹyọ mọ ọwọ ati ẹsẹ lati fihan pe Onifa ni oun.
- Wo ìdí tí Osun fi kede ìsinmi fún ọdún ìṣẹ̀ṣe, tàwọn ìpínlẹ̀ yókù kò dáhùn,
- Wo ewu tó rọ̀ ma kí wọn sin ọba tó ṣètùtù nílànà ẹ̀sìn Krìsítẹ́nì àti Islam
- Egúngún bá òṣèrébìnrin lòpọ̀ nínú eré, àwọn Eléégún yarí
- Ẹ wo àwọn obìnrin tí kìí ṣe ọmọ Yorùbá tó jẹ́ ayaba ní ààfin ilẹ̀ Káàárọ̀ oòjíire
- Àwọn ẹ̀gbọ́n mi ọkùnrin dá pín ogun bàbá wa, wọ́n ní pé obìnrin ni mí- Onyinye
Orisabunmi Olasanya ni orukọ ọmọge ọhun, to si kawe gboye imọ ijinlẹ akọkọ ni fasiti.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Orisabunmi salaye ọpọ ipenija to n koju lati ọdọ awọn ọkunrin tori pe o jẹ ẹlẹsin ibilẹ.
Bakan naa, o tun sọ bawọn ẹlẹsin igbalode meji to ku se n fi ẹsin naa se amulumala nitori pe wọ̀\n maa n tọ baba oun wa, tii se babalawo lati se oogun.
Orisabunmi tun fikun pe oun ti lọ si sọọsi ri, ti oun si ti se akọrin ri ninu sọọsi amọ oun pada sidi ẹsin ibilẹ nitori pe ẹsin isẹse nikan lo pe.
- Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì OAU dáwọ́ jọ lu akẹ́kọ̀ọ́jáde pa torí ẹ̀sùn pé ó jí fóònù
- Biola Adebayo, gbajúmọ̀ òṣèré tíátà, di ọlọ́mọ lẹ́yìn tó wá abánigbóyún fún ìgbà mẹ́ta láàrin ọdún méjì láì rí
- "Alhaji ni ọkọ́ mi, èmi jẹ́ Wòlíì obìnrin, ẹ̀sìn kò dá ìjà sílẹ̀ nínú ìgbéyàwó àádọ́ta ọdún wa "
- Ọmọge mẹ́rin lọ patí ọjọ́ ìbí ní Ile-Ife, afurasí afinisòwòẹrú fi òògùn orun sínú ọtí wọn láti gbé wọn lọ ṣẹrú ní Libya
- Wo àwọn àìsàn tó le ṣúyọ ní àgọ́ ara lásìkò ààwẹ̀



