Akomolede ati Asa: Ọ̀rọ̀ Asopò ni á ń gbéyẹ̀wò pẹ̀lú Arabìnrin Tope Atoyebi láti Ilorin
Mọ̀ sii nipa iṣẹ ti Oro Asopo n ṣe ninu gbolohun ede Yoruba- Tope Atoyebi
Lori eto Akomolede ati Asa lori BBc Yoruba ni a wa yii.
Oro Asopọ ni koko girama ni koko ti a n gbe yẹwo loni lori eto naa.
- Àwọn Olùkọ́ Akure pegedé lórí ètò Akomolede àti Aṣa lórí BBC Yorùbá
- Awẹ́ Gbólóhùn ni kókó tí à ń gbéyẹ̀wò lónìí lórí ètò Akomolede- Olùkọ Olajide
- Wá kẹ́kọ̀ọ́ nípa ègé ọ̀rọ̀ ohùn Yorùbá tí a mọ̀ sí Sílébù
- Mọ̀ sií i nípa Oba Yesufu Asanike , Olubadan tí kìí fi ọ̀rọ̀ sí abẹ́ ahọ́n sọ kódà níwájú sọ́jà
- August Agboola Brownie, ọmọ Yorùbá tí wọ́n n wárí fún ní Poland
- Ṣé lóòtọ́ọ́ ni pé ìtọ̀ àti imí màálù le wo ààrùn coronavirus?
- Irú ẹ̀dá wo ni Lamidi Adeyemi? Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo
- Wo ìgbéyàwó olówó iyebíye tí awakọ̀ Kabúkabú ti jẹ̀bùn ọkọ N3.4m
- Wo ìtàn ọgọ́ta ọdún Nàíjíríà nínú àwòrán mẹ́fà péré
Kini ọrọ Asopo?
Iṣẹ wo lo n ṣe ninu gbolohun?

Bawo lo ṣe le da a mọ ninu gbolohun?
Awọn ibeere yii ati omiran ni Arabinrin Tope Atoyebi lati ile ẹkọ Emmanuel Baptist College, Tanke ni ilu Ilorin ni ipinlẹ Kwara ni aarin gbungbun Naijiria.





