Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí
Koko wo lo wa ninu ẹkun iyawo?
Alagba Tayo Saanuade lati ile iwe Baptist Girl's Grammar School ni Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni guusu Iwo oorun Naijiria ni olukọ wa loni.
Eto Akomolede ati Asa lori ikanni BBC Yoruba lo n ṣagbeyẹwo Ekun Iyawo fun ẹyin ololufẹ wa.

Eto Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba yii n waye pẹlu ajọṣepọ BBC ati ẹgbẹ onimọ YSAN ati ẹgbẹ Akomolede Naijiria lapapọ
Mọ sii nipa akoonu ẹkun iyawo.
Iru ewi wo ni ẹkun iyawo?
Nigba wo ni a n sun ẹkun iyawo?
Awọn wo lo n sun un?
- Olùkọ́ Bunmi Femi Amao ló ń kọ́ wa ní Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán lonìí
- Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka
- Ẹ̀gbọ́n mi tán ìṣòro mi nípasẹ̀ ṣíṣe ẹ̀ya ara àtọwọ́dá fún mi- Ubokobong Sunday
- Ẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Adelé Ọba Alade Idanre ló rí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàárín òun àti Ọba Aroloye
- Ta ni Wolii Olapade Agoro tó re ibi àgbà ń rè tí ayé ń pariwo rẹ̀ yìí?
Koko wo lo n jẹyọ nibẹ?
Agbegbe wo lo wọpọ si julọ?
Ẹ wa nkan fidi le ki ẹ wa kọ ẹkọ.

- Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀
- Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀
- Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá
- Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀
- Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá


