Ajibade Babalade: Àwọn ọmọ Naijiria ṣèdárò gbajúgbajù agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tó dolóògbè

Oríṣun àwòrán, Others
Awọn ọmọ Naijiria ti n ṣedaro gbajugbaja agbabọọlu Naijiria, Ajibade Babalade to se alaisi ni ẹni ọdun mejidinlaadọta.
Babalade to kopa ninu idije Africa Cup of Nations ni ọdun 1992, lo ku lojiji lẹyin ti o ni aisan ọkan.
Akẹgbẹ rẹ, Ike Shorunmu ni ileewosan akọkọ ti wọn gbe e lọ kọ ọ, ko to di wi pe wọn gbe lọ si ileewọsan ẹkọni ti ilu Ibadan, tii o si dakẹ ki wọn to wọle sinu ileewosan naa.
Ajọ to n risi ọrọ erebọọlu ni Naijiria. NFF lasiko ti wọn n ṣedaro agbabọọlu ọwọ ẹyin to doloogbe naa loju opo Twitter wọn, sọ wi pe ibanujẹ ni iroyin iku rẹ jẹ fun awọn.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 1
Awọn ololufẹ rẹ ranti iṣẹ takuntakun to ṣe lati gba ami ẹyẹ lasiko idije Afcon 1992 to waye ni orilẹede Senegal.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 2
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 3
Arakunrin Nasiru Suleiman ni Babalade ni laipẹ ki o to ku ni o ṣi fẹran aworan ti oun fi sita nigba ti oun ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọmọ rẹ akọkọ.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 4
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 5
Bakan naa ni awọn ololufẹ erebọọlu ni Naijiria fikun wi pe ipa takuntakun ti Babalade ko ninu ẹgbẹ agbọọla Enyinba lo jẹ ki wọn gba ami ẹyẹ CAF Champions League nigba rẹ.
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post, 6
- Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz
- Ènìyàn 156 míràn ló tún kó Coronavirus ní Nàìjíríà ní ọjọ́ Ẹtì
- Olórin Kano tí wọ́n dájọ́ ikú fún pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn
- Nàìjíríà làwọn ní ìfẹ́ sí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Russia ṣe
- Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbárà iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko (EKDC)
- Àwọn dókítà yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódí lọ́jọ́ Ajé
Iyawo Ajibade Babalade ati ọmọ rẹ mẹta ti wọn n gbe lorilẹ-ede Amerika lo gbẹyin rẹ.
Ni Igba aye rẹ, Babajide Shorunmuti jẹ akọnimọọgba fun ẹgbẹ agbabọọlu Niajiria, Shooting Stars.
Bakan naa lo gba bọọlu loke okun fun awọn orilẹ-ede bii Ivory Coast (African Sports0 , Korea (Anyang LG Cheetahs), Austria (SK Sturm Graz) ati ẹgbẹ agbabọlu Mohun Bagan AC ni orilẹ-ede India.















