You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Davido, Yomi Fabiyi and Baba Ijesha: Davido sí Yomi Fabiyi: Mùmú ni ẹ́
Gbajugbaja ọdọ olorin ọmọ Naijiria ti bu ẹnu atẹ lu bi oṣere Yomi Fabiyi ṣe farahan nibi Ifẹhonu han to ṣe lanaa.
- Ṣé ǹkan oṣù rẹ ń dà hìì hìì lẹ́yìn tóó gba abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19? Ẹ gbọ́ tuntun lẹ́nu àwọn Dókítà
- Kí ló mú Yomi Fabiyi àti Iyabo Ojo máa sá aṣọ ìdọ̀tí ara wọn síta?
- Wo bí ìwọ́de Yomi Fabiyi nítorí ọ̀rọ̀ Baba Ijẹsha to wa ni àhámọ̀ ọlapàá ṣe n lọ nílùú Eko
- Ọkùnrin kan bí ẹgbẹẹgbẹ̀rún ni mi, àmọ́ o le darapọ̀ mọ́ ìwọ́de fún Baba Ijẹsha tí o ba tako ìfìyàjẹni
- A ti fòfin de dída màálù ní gbangba káàkiri ilẹ̀ Yorùbá, Ibò àti ìhà Gúúsù Gúúsù - Àwọn gómìnà yarí
- Àwọn ọmọ Naijiria yóò rí akitiyan ìjọba láti yanjú ètò àbò tó mẹ́hẹ láìpẹ́ - Lai Mohammed
- Ẹni tó bá ní láàkàyè, a mọ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn, àwà ti kọ lẹ́tà, èsì t'Ọ́lọ́pàá sì fún wa rèé - Yomi Fabiyi
- Òṣèré tíátà Yorùbá míràn tún kó sí gbaga ọlọ́pàá
Yomi Fabiyi ṣe iwọde naa nitori akẹgbẹ rẹ, Olarewaju Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijesha ti wọn ti mọ ahamọ ọlọpaa fun ẹsun ifipaba ọmọde lopọ atawọn ẹsun mii to rọ mọ ọ.
David Adeleke ti ọpọ mọ si Davido OBO fi fidio ifẹhonuhan Yomi Fabiyi sita to si kọ akọle eebu le e lori pe "mumu ni ẹ tori o ko wọ ibomu".
Davido n tọka si pe ninu gbogbo awọn ti wọn jọ n wọde, Yomi Fabiyi nikan ni ko wọ ibomu.
Wiwọ ibomu jẹ aṣẹ ijọba Naijiria paapaa lasiko yii ti wọn ṣẹ tun ni iṣi ati ẹda Coronavirus mii ti rapala wọ Naijiria.
Yomi Fabiyi n ja fun pe wọn ti jẹ ki Olanrewaju Omiyinka iyẹn Baba Ijesha pẹ latimọle ju lai tii gbe e lọ ile ijọ tori wọn wa ni iyanṣẹlodi, o ni o yẹ ki wọn da a silẹ pẹlu beeli.
Ẹwẹ loju opo Twitter olorin Davido, awọn to lu Davido lọgọ ẹnu tako pe o pe Yomi ni Mumu wa:
- Ikú kò m'ọmọdé, kò màgbà, ẹ gbàdúrà fún ìdílé mi àti aya pẹ̀lú ọmọ olóògbé- Pásítọ̀ Adeboye
- Bó ṣe nípasẹ̀ ọkada ni tàbí ọkọ̀ ojú omi tàbí láti inú ihò ilẹ̀, ẹ wá ọ̀nà láti fi Naijiria sílẹ̀- Pasitọ Paul Adefarasin
- Ààwẹ̀ Ramadan ṣì tẹ̀síwájú dí Ọjọ́ọ̀rú, a kò tíì rí òṣùpá- Supreme Council (NSCIA)
- Ọmọdé méje àti olùkọ́ kan jẹ́ Ọlọrun nípè lẹ́yìn tí agbébọn ẹni ọdún 19 ṣíná ìbọn bolẹ̀ nílé ẹ̀kọ́ wọn
- Ẹ̀yin ọmọ Naijiria, ẹ gbé ohùn àdúrà sókè nítorí ètò ààbò Naijiria - Buhari
- Kàyèéfì! Wo ìdí tí àlùfáà ìjọ Aguda fi ń kó ère ìṣẹ̀nbáyé pamọ́?