Kiki Osinbajo: Tó bá yá owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, máa gbìyànjú láti da padà
Kiki Osinbajo, tii se ọmọ igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo ti salaye fun BBC Yoruba nipa awọn ọna ti eeyan fi le lo ori ayelujara lati mu ki okoowo gbooro si.
Bakan naa lo sọrọ lori awọn ipenija tawọn ọdọ Naijiria n koju ninu isẹ ati okoowo wọn, to si fi awọn iriri to ti la kọja bii olokoowo se apẹrẹ.
Ko tan sibẹ, Kiki tun sọrọ nipa ọna to gba bẹrẹ okoowo ati ipenija to n koju awọn obinrin aye ode oni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Wo orúkọ tuntun tí Facebook yóò má jẹ́ láti àkókò yíì lọ
- Wọ́n gbé ọmọ mi tó jẹ́ Babaláwo Sunday Igboho, a kò mọ ìrìn rẹ̀ láti oṣù mẹ́ta
- Seyi Makinde kò láṣẹ láti fi ẹ̀rọ CCTV sí ọgbà ẹ̀wọ̀n - Aregbesola
- Ọkùnrin kan wọ gàù torí ọ̀rọ̀ tó fi ránṣẹ́ sí aya aláya lórí Whatsapp
- "Ẹlẹ́wọ̀n Abolongo pa méjì lára ọdẹ ìbílẹ̀ lásìkò tà ń ṣà wọ́n kiri ìgboro Oyo"
- Ṣé lóòtọ́ ni CBN n pín àádọ́ta bílíọnù eNaira lọ́ọ̀fẹ́ fún aráàlú?
- "Àwa ológun fipá gbàjọba ní Sudan láti dènà ogun abẹ́lé ni"
- Ìwà ìkà sí Yorùbá ni bí ìjọba ṣe ti bodè Seme láti 2019 - Gani Adams
- Ọmọ onílẹ̀ mẹ́ta kó sí páńpẹ́ ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn ìpànìyàn
- Wo ohun tí Yinka Alaseyori sọ nipa Tope Alabi ní àyájọ̀ ọjọ́ ìbí rẹ̀
- Ọmọ onílẹ̀ mẹ́ta kó sí páńpẹ́ ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn ìpànìyàn


