June 12: M.K.O Abiola: Eyi ni àwọn ńkan tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa rẹ̀
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Moshood Kashimaawo Olawale Abiola lo dije dupo aarẹ Naijiria lọdun 1993 labẹ ẹgbẹ oṣelu SDP.
Oun ati Alhaji Babagana Kingibe ni wọn jọ dije labẹ ẹgbẹ oselu SDP nigba naa.
Ojọ kejila, oṣu kẹfa, ọdun 1993 ni wọn ṣeto idibo naa nibi ti ọpọ gba pe Abiola gbegba oroke ki ijọba Babangidea to wọgile e nigba naa.
Ojọ keje, oṣu keje, ọdun 1993 ni MKO Abiola jade laye nigba naa.
- Abdulsalami ní kò sẹ́ni tó pa MKO Abiola, àìsàn ló pa á, ẹbí Abiola yarí
- Boris Johnson kéde pé òun ti fipò olóotú Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí sílẹ̀
- Pásítọ̀ 'Ondo Church' tó kó àwọn ọmọ ìjọ pamọ́ sí àjà ilẹ̀ fojú ba ilé ẹjọ́
- Ṣé lóòótọ́ ni ẹgbẹ́ òṣèlú PDP Eko yan Funke Akindele gẹ́gẹ́ bí igbákejì olùdíje gómìnà-
- Ayẹyẹ ìgbaniwọlé sínú ẹgbẹ́ òkùnkùn bẹ́yìn yọ, wọ́n lu ọmọ ẹgbẹ́ tuntun pa
- Ọwọ́ tẹ afurasi olè méjì tó jí àgbò iléyá ní Ogun
- Ìpalẹ̀mọ́ ọjọ́ Arafah, ìmọ̀ràn mẹ́wàá rèé láti lè mú Hajj rọrùn f'álálàhájì
- Ìgbẹ́jọ́ Ike Ekweremadu ní London ń tẹ̀síwájú lónìí











