Saliu Atagiroso: Kìí ṣe gbogbo eèyàn lò lè darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ àwa tí à ń pè sí orí rédíò
Sẹ lóòtọ́ ni pé àìníṣẹ́ lọ́wọ́ ló ń yọ àwọn tó máa ń pè sórí ètò rédíò lẹ́nu?
Oriṣiriṣi ẹgbẹ̀ tuntun ni awọn eeyan n da silẹ fun idagbasoke awujọ.
Egbe awọn to maa n pe lori eto sori afẹfẹ naa ti bẹrẹ ni Naijiria, eyi ti wọn pe ni Regular Callers On Radio Association.
Alhaji Saliu Atagisoro to jẹ alaga ẹgbẹ naa ṣalaye idi ti wọn ṣe da ẹgbẹ naa silẹ fun BBC.
O ni pe ki idagbasoke le ba awujọ ni wọn ṣe n pe sori eto nigba gbogbo.
- INEC gbọ́dọ̀ mú ìwé ẹ̀rí ẹ̀kọ́ Ademola Adeleke síta, ilé ẹjọ́ pàṣẹ fún alákoso àjọ ètò ìdìbò nípínlẹ̀ Osun
- Nkan mẹ́jọ tí o le ṣe láti dáàbò bo ara rẹ tí o bá ń rìn lójú pópó
- 'Àwọn èèyàn sọ fún bàbá mi pé kó má rán mi lọ sílé ẹ̀kọ́ 'torí mo jẹ́ obìnrin'
- Púpọ̀ àwọn tó ń bu mi pé mo yan Shettima gẹ́gẹ́ bíi igbákejì mi ló nífẹ̀ẹ́ sí ipò náà – Tinubu
- Mo fẹ́ díje fún ipò àárẹ ní 2024 láti gbé ògo America dìde lẹ́ẹ̀kan sí i - Trump
- Àwọn Olóṣèlú ti ba ǹkan jẹ́ jú ní Nàìjíríà, Yorùbá ló kàn ṣùgbọ́n....- Adewole Adebayo
Alhajiu Saliu Atagisoro salaye fun BBC nipa awọn ipa rere ti ẹgbẹ to n pe sori afẹfẹ yii ti ṣe lataari bi wọn ṣe n pe sori eto ti ijọba si n gbọ.
Bakan naa lo mẹnuba awọn amuyẹ ọmọ ẹgbẹ naa ni eyi ti ko nii ṣẹ pẹlu ẹgbẹ oṣelu kankan ni Naijiria.
- 'À-wọn obìnrin tó n fi ọṣẹ tó ní kẹ́míkà sí irun wà nínú ewu jẹjẹrẹ ilé ọmọ'
- Ẹ̀yin gómìnà, ẹ fún wa láàyè láti kojú àwọn agbébọn lòpópónà Èkó sí Ìbàdàn
- Wo àwọn ohun mánigbàgbé mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ nípa Lam Adesina lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá tó jáde láyé -
- Ẹ̀tọ́ mi kọ́ ni àwọn gómìnà tì inú n bí nínú ẹgbẹ òṣèlú PDP n jà fún - Goodluck Jonathan
- Àdó olóró tí ìjọba fi ránṣẹ́ sí àwọn ọmọ ogun ọlọ̀tẹ̀ pa ọ́pọ́lọpọ̀ aráàlú ní Ethiopa
- Àtúpalẹ̀ àwọn àròsọ márùn ún nípa àyípadà ojú ọjọ́ tí kìí ṣe òótọ́
- Ohun tó fa rògbòdìyàn lẹ́yìn tí wọ́n yan Ọba tuntun ní Ikirun rèé