Shonekan's burial: Òní ní wọ́n yóò tẹ ara olóògbé Ernest Shonekan sí itẹ́ ni Ebony Vault ni Ikoyi ni ilu Eko

Oríṣun àwòrán, @Dapo Abiodun
Ètò Ìsìnkú olóògbé Ernest Shonekan ti ń wáyé báyìí nile ijosin onigbagbo Cathedral Church of Christ, Marina ni ipinle Eko.
Content is not available
View content on FacebookBBC kò mọ̀ nípa àwọn ohun tí ó wà ní àwọn ojú òpó tí ó wà ní ìta.End of Facebook post, 1
Loju Opo Facebook Gomina Dapo Abiodun to n tuko ipinle Ogun ni a wa yii to n safihan bi eto isinku naa se n lo
Content is not available
View content on FacebookBBC kò mọ̀ nípa àwọn ohun tí ó wà ní àwọn ojú òpó tí ó wà ní ìta.End of Facebook post, 2
Content is not available
View content on FacebookBBC kò mọ̀ nípa àwọn ohun tí ó wà ní àwọn ojú òpó tí ó wà ní ìta.End of Facebook post, 3
- Shonekan ò kú o, ko ko ko lara le!
- Ààrẹ fìdíhẹ Naijiria tẹ́lẹ̀, Ernest Shonekan ti jáde láyé
- Obasanjo, Osinbajo, Shonekan àtàwọn èèkàn ọmọ Ogun nínú ìṣèjọba Nàìjíríà.
- Wo àwọn ààrẹ alágbádá tó ti jẹ ní Nàìjíríà láti 1960 di àkókò yìí
- Obasanjo, Osinbajo, Shonekan àtàwọn èèkàn ọmọ Ogun nínú ìṣèjọba Nàìjíríà.
- Ọkọ mi pa ọmọ wa mẹ́ta, o kó òkú wọn sínú fírísà - Milliscent Amadikwa

Oríṣun àwòrán, @Dapo Abiodun
Die lara awọn aworan to jade nibi eto isin ale idagbere ti Onigbagbo fun oloogbe Shonekan ree:

Oríṣun àwòrán, @Dapo Abiodun

Oríṣun àwòrán, @Dapo Abiodun
Kini o n ṣẹlẹ lonii?
Oni ọjọ kẹrin, oṣu keji, ọdun 2022 ni eto isinku Aarẹ Fidihe Naijiria nigba kan ri, Oloye Ernest Shonekan n waye.Ààrẹ fìdíhẹ Naijiria tẹ́lẹ̀, Ernest Shonekan ti jáde láyé
Ṣaaju ni won ti ṣeto isin idagbere fun oloogbe naa to dagbere faye lọjọ kọkanla, oṣu kinni , odun 2022.
Eni ọdun marunlelọgọrin ni Shonekan nigba ti o dagbere fun aye pe o digboṣe.

Oríṣun àwòrán, @Shonekan
Ta ni Shonekan?
Shonekan ni ọga agba ileeṣẹ United African Company of Nigeria Plc, UAC, ki ọgagun Ibrahim Babangida to yan gẹgẹ bii Aarẹ fidihẹ lọdun 1993.
Wọn bi Shonekan lọjọ kẹsan an, ọsu Karun un, ọdun 1936 niluu Eko.
O kawe ni ile ẹkọ CMS grammar school niluu Eko ati Igbobi College, ko to tẹsiwaju kẹkọgboye ni fasiti ilu London ati Harvard Business School.
Nibo ni Olopogbe naa dagbere si?
Iroyin ni pe Oloogbe Ernest Shonekan dagbere si ile iwosan Ever Care Hospital ni ipinle Eko.
Ojọ kẹtadinlogun, ọṣu kọkanla, ọdun 1993 ni Oloogbe Ogagun Sani abache gba ijọba Fidihe naa lọwọ Shonekan to n ṣe e lati ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹjọ, ọdun 1993
Bawo ni Isin Idagbere eto isinku naa ṣe waye?
Wọn ṣeto isin idagbere alẹ ikẹyin ati aisun onigbagbo fun Oloogbe Ernest Shonekan ni ale ana, ọjọ Bo, ọjọ kéta, ọsu keji, ọdun yii.
This article contains content provided by Instagram. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read Instagram cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of Instagram post
Nibẹ naa ni awọn eekan bii awọn Gomina, awọn Aarẹ nigba kan ri, Aṣoju ṣofin, awọn biṣoọbu ati awọn eekan mii bii Senato Ibikunle Amosun ati aya re.
Loju opo Instagram goldmyne yii lo ti ṣafihan diẹ ninu eto naa ati bi ọmọkunrin oloogbe Shonekan ṣe n fi imoore han nibi eto naa lọwọ a\won to wa nibẹ.
- Iná jó oko Obasanjo to wà ní ìpínlẹ Benue, Ẹbọra Òwu bínú, Ortom ni kí wọ́n bẹ̀rẹ̀ ìwádìí ní kíá
- Okòòwò márùn ún tí o lè bẹ̀rẹ̀ nínú ilé rẹ̀
- Abdulsalami ní kò sẹ́ni tó pa MKO Abiola, àìsàn ló pa á, ẹbí Abiola yarí
- Ṣé o mọ̀ pé o leè kó Covid pẹ̀lú ọmọ ìka ẹ̀sẹ̀ rẹ̀ láì mọ̀?
- Ọwọ́ aráàlú ní ètò ìdájọ́ òdodo Nàìjíríà wà, kìí ṣé ọdọ àwọn onímọ̀ ètò ìdájọ́- Osinbajo
- Orílẹ̀-èdè North Korea ṣe ìfilọ́lẹ̀ àdó olóró tó tóbi jùlọ láti ọdún 2017














