Oyo prison break: Ìbúgbàmù ọ̀hún kò mú ẹ̀mí ẹnikẹ́ni lọ

Oríṣun àwòrán, NPS
Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe ibugbamu mii tun ti waye ni ọgba ẹwọn to wa niluu Abolongo, ni ipinlẹ Oyo.
Ibugbamu ọhun to waye ni ita ọgba ẹwọn naa ko mu ẹmi ẹnikẹni lọ.
Iroyin ni o ṣeeṣe ko jẹ pe ọkan lara awọn ado oloro ti awọn agbebọn to kọlu ọgba ẹwọn naa gbin sibẹ lasiko ikọlu wọn lọjọ Ẹti to kọja lo ṣẹṣẹ bu gbamu.
- Wo àbọ̀ ìgbìmọ̀ olùwádìí lórí ilé Kéú tó lu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ bí aṣọ òfì ní Kwara
- Boko Haram fi tipa fẹ́ mi fún ọkọ àmọ́ ìfẹ́ rẹ̀ gbóná lọ́kàn mi ni ń kò fi sá kúrò
- "Ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ yóò tẹ̀síwájú ní Naijiria títí di ọdún tó ń bọ̀"
- Ìfẹ́ ńlá rèé o! Ọmọbabìnrin pàdánù ipò ọlá rẹ̀ láti fẹ́ atàpátadìde ní ọkọ
- Saraki sọ̀rọ̀ lórí bó yá òun lè darapọ̀ APC láti dupò ààrẹ
- Ọkọ àti ìyàwó ṣàlàyé ohun tó jẹ́ kí wọ́n ta ọmọ wọn ní N200,000 tí ṣe $500
- Ọlọ́pàá Ogun ń wá akẹ́kọ̀ọ́ tó rán jàndùkú lọ lu àwọn olùkọ́ rẹ̀ lálùbami lọ́gbà ilé ẹ̀kọ́
- Wo bí o ṣe le ná owó eNaira tí Naijiria fẹ́ ẹ̀ má lò báyìí
- Naijiria yóò dàrú tí ìjọba àpapọ̀ bá le kéde àwọn jàndùkú gẹ́gẹ́ bíi agbésùmọ̀mí - Sheikh Gumi
Ẹwẹ, awọn agbofinro ti ṣabẹwo si ọgba ẹwọn naa lati wo bi nnkan ṣe ri ati ọna ti wọn yoo gba lati yanju ọrọ naa.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ọjọ Ẹti to kọja ni awọn agbebọn kan ya bo ọgba ẹwọn naa ni nnkan bii aago mẹwaa aṣalẹ, ti wọn si tu awọn ẹlẹwọn silẹ.
Ọkan lara awọn ọde ilu naa ṣalaye fun awọn akọroyin pe iye agbebọn to kọlu ọgba ọhun to aadọta, ti oun si mu mẹrin balẹ lara awọn,
Wayi o, wọn ti ri mu pada lara awọn ẹlẹwọn to salọ lasiko ikọlu naa.









