Ibadan Chief kidnap: Báyìí nì géńdé agbébọn ṣé na'wọ gán Olóyè Tafa àti ìyàwó rẹ́ lásìkò wẹli-wẹli òjò

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agbebọn tẹnikan ko mọ ti gbe Baalẹ kan ati aya rẹ nilu Ararọmi to n bẹ ni agbegbe Bakatari nilu Ibadan, olu ilu ipinlẹ Ọyọ.
Iroyin sọ wi pe awọn agbebọn naa yawọ ilu Ararọmi ni Bakatari lalẹ ọjọ Iṣẹgun wọn si gbe Baalẹ, Oloye Tafa Apanpa ati aya rẹ lọ.
Bakatari ti o jẹ ọkan lara awọn ilu to n bẹ ni ijọba ibilẹ Ido wa ni opopona marosẹ Ibadan si Abẹokuta.
- Àwọn Ọba tí kò bọ̀wọ̀ fún ìṣẹ̀ṣe ni wọ́n ń jí gbé - Ọwá Oòyè Okemesi
- Ọlọ́pàá, fijilanté àti ọdẹ ìbílẹ̀ dóòlà obìnrin mẹ́ta lọ́wọ́ ajínjigbé l‘Oyo
- Ohun tí Ọlọ́pàá mọ̀ nípa bóyá Agbébọn jí ọmọ ìjọ RCCG mẹ́jọ tó ń lọ jèrè ọkàn gbé rèé!
- Ọlọ́pàá Ondo: Ètò ààbò kò mẹ́hẹ ní ọ̀nà Akure sí Ikere
- Bí Kábíyèsì Ọba Tajudeen Omotayo ti Imope ṣe fara gbá mílíọ̀nù gọbọi kó tó bọ́ lọ́wọ́ ajínigbé - Ìdílé Alademeta
Bakan naa lo jẹ ilu to paala laarin ipinlẹ Ogun ati Ọyọ.
Alaye ti awọn olugbe agbegbe naa ṣe ni pe ijinigbe Baalẹ ati aya rẹ waye lalẹ l'ọjọ Iṣẹgun ninu wẹliwẹli ojo to rọ n'Ibadan.
Bakan naa ni wọn fi kun ọrọ wọn wi pe ko si ẹni to mọ ibi ti Oloye naa ati aya rẹ wa titi di asiko yii.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Adewale Osifeso fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ.
O ni awọn agbofinro ti bẹrẹ iṣẹ iwadi lori ọrọ naa.
- Ṣé lóòtọ́ ni olè kan wọlè fipá bá ìyá 80 lòpọ̀ nípìnlẹ̀ Ondo?
- Alága ìjọba ìbílẹ̀ Eti-Osa, Eko tí jádé láyé lẹ́yìn tó ṣe àìsàn
- Kò sí ìpínlẹ̀ tí ijọba mi kò tíì fọwọ́ bà sí rere- Ààrẹ Muhammadu Buhari
- Ẹranko àìmọ́ kan wọ Nàìjíríà, ó pa ènìyàn mẹ́rin ní Benue- ilé iṣẹ́ ọmọogun ni ìròyìn òfegè ni
- Pipa ní wọ́n gbọ́dọ̀ pa àwọn agbébọn tí wọ́n ń jí àwọn ènìyàn gbé, ẹ da ọ̀rọ̀ Sheik Gumi nù -Aisha Yesufu
- Ẹ̀wọ̀n ọdún méje gbáko ni adájọ́ sọ pé kí Farouk Lawan fi ṣara ridin!















