Ogbomoso: Wo àwọn ibùdó ìṣẹ̀ǹbáyé tó mú kí ìlú yìí gbajúmọ̀
Yoruba ni ilu ẹni, ni ilu ẹni, ko si si ibi to dabi ibi ta gbe bi ni.
Lori eto Ẹ kalọ si ilu mi ni osu yii, ilu Ogbomoso ni BBC Yoruba balẹ si lati fi oju se mẹrin awọn ibi pataki to jẹ manigbagbe ni ilu naa.
Lẹnu irinajo wa silu Ajilete yii, Ogbomoso ọmọ afogboja, ilu ti wọn ti n jẹ ọka tan, ki wọn to mu ẹkọ yangan, a se alabapade oniruuru ohun amoriwu lọkan o jọkan.
- Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba wọn ní ọdùn tó ti pẹ́ díẹ̀ sẹ́yìn
- Irọ́ ní pé bàbá wa, Soun Ogbomoso paradà di ọmọ tuntun, báyìí ni àwọn ọ̀rẹ́ ṣe dalẹ̀ rẹ̀ tí wọ́n pa á
- Ṣé ẹ mọ̀ pé olóògbé Ìjàpá tó kú lẹ́ni ọdún 344 yìí kò gba abẹ́rẹ́ rí?
- Wàwúù!!! Lẹ́yìn ọmọ márun-ùn, wo bí ìyàwó àgbẹ̀ se tún bí ìbaàrùn-ún ní Ogbomoso láì ṣe iṣẹ́ abẹ
- Fulani tiraka láti kógun ja Ogbomoso àmọ́ ẹbọ tí wọn rú rèé - Ọmọọba Itabiyi
- Wàwúù!!! Lẹ́yìn ọmọ márun-ùn, wo bí ìyàwó àgbẹ̀ se tún bí ìbaàrùn-ún ní Ogbomoso láì ṣe iṣẹ́ abẹ
- Alao Akala ló da ìgbìmọ̀ lọ́balọ́ba Oyo rú, àwa ọba kò jìjà àgbà - Onpetu Ijeru
A kan si mọsalasi akọkọ nilu Ogbomoso, ati sọọsi St. David Anglican, akọkọ ti wọn kọ lọdun 1854.
Bakan naa la de aafin ọba Soun tilẹ Ogbomoso ati ibudo ti baba agba n gbe ko to ku, eyiun ijapa to wa ni aafin, to lo ọdun to le ni ọọdunrun laye.
Irinajo wa naa tun gbe wa de ibudo Ogun o jalu, to n se ọwọn iranti pe ogun ko ko ilu Ogbomoso ri.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa
- Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é
- Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango
- Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ
- Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko
- Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn
- Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba
Ẹnu ko gba iroyin, ẹ maa ba wa kalọ silu Ogbomoso loni, lati fi imọ kun imọ yin nipa ilu olokiki naa.





