Oba Olayode: Egbo to ti fẹẹ́ jiná ni ẹ tún ń fi èékáná te yìí - Omo Soun Ogbomoso II
Gbogbo awọn ti BBC Yoruba fọrọ wa lẹnu wo nipa bi Oba Olayode keji to ti jẹ Soun ti ilu Ogbomoso ri nigba aye rẹ ṣe waja lo fẹrẹẹ ma fẹ sọ bi o ṣe ṣẹlẹ tori o jẹ ibanujẹ ọkan fun wọn.
Ọpọlọpọ awuyewuye lo si rọ mọ ipapoda Oba alade yii gẹgẹ bi a ṣe ṣewadii.
Laarin ọdun 1966 si ọdun 1969, iyẹn ọdun mẹta pere ni asiko Oba emmanuel Olajide Olayode lori itẹ Ọba gẹgẹ bii Soun.
- Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo "Make-up" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́
- Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà
- Ẹ gbọ́ ohun tí Desmond Elliot sọ lórí ayélujára tó bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú
- Báyìí ni 50kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú "Ali Must go" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ
- Wo ohun tí Fashola rí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate tó ń fa ariwo lórí ayélujara
- Wo àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS
- Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti
- Àwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn tó sọ̀rọ̀ tí ará ìlú fà ìbínú yọ
"Egbo to ti fẹẹ́ jina ni ọrọ ti ẹ tun n fi eekan te yii".
Latori ọmọ bibi inu Oba Olayode, to fi mọ gbogbo mọlẹbi lo tan imọlẹ si ẹdun ọkan wọn nipa bi Oba yii ṣe waja.
Wọ́n jẹ ko di mimọ pe ẹni ti tara ile tara oko fẹran gan ni Oba Olayode bo tilẹ jẹ pe ija oye wa lori didi Soun Ogbomoṣo.
Oun ni Ọmọwe akọkọ ti yoo jẹ Soun ti Ogbomoṣo ṣugbọn nigba to di ọdun 1969... itan yipada biri.
Ọrọ ko lee dun lẹnu wa bii ọlọrọ bi wọn ṣe sọ ọ ninu fidio to wa loke yii.
- Taa gan ló ni Lekki Toll gate láàrin aráàlú àti Asiwaju Tinubu?
- Ojú àwọn tọ́wọ́ ti tẹ̀ lára àwọn tó jí 'tíá rọ̀bà ọ̀kadà', fíriìjì, ẹ̀rọ ata kó nílée Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin rèé
- 'Ó ku ọ̀la kí Isiaka ṣe 'Freedom' ní àṣìta ìbọn bà á ní Ogbomọshọ '
- Mo ṣèlérí láti ṣe ju ohun tí mo ti ṣe lọ fún ẹbí àwọn tó kú torí EndSARS - Seyi Makinde