Sadiq Daba biography: Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sadiq Daba 'Inspector Waziri' nínú sinimá October 1 tó jáde láyé rèé

Oríṣun àwòrán, Premium times
Gbajumọ oṣere ni Sadiq Abubakar Daba ti ọpọ mọ si Sadiq Daba. Akọṣẹmọṣẹ igbohunsafẹfẹ si tun ni pẹlu.
Bi o tilẹ jẹ pe ọmọ ilu Kano ni, Ilu Freetown lorilẹede Sierra Leone lo gbe dagba ki o to pada si orilẹede Naijiria nigba to pe ọmọ ọdun marundinlogun.
Ileewe St Edwards Secondary school ni ilu Freetown lo lọ fun ẹkọ girama ki o to lọ gba iwe ẹri imọ ijinlẹ ni fasiti Ahmadu Bello University ni ilu Zaria.
- Baba tó dàbí MC Oluomo láyé yìí kò sí, ẹni tó bá níi, ó ní ohun gbogbo- Ọmọ MC Oluọmọ
- Báwo ní Ọba Rilwan Akiolu tí ìlú Eko ṣe ní $2 million àti N17 million sí inú àfin rẹ̀?
- Wọ́n tún yìnbọn níbi àpèjẹ 'Ẹ káàbọ̀' tí wọ́n ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Zamfara lẹ́yìn àṣẹ Buhari
- Ìjà ti parí, a ti gbà láti má a gbé ounjẹ wá sí ilẹ̀ Yoruba padà'- Hausa-Fulani Ọlọ́jà
- Ọlọrun má jẹ́ kí a jẹ́ gbèsè lókù báyìí tí a kò kó ọjá lọ sílẹ̀ Yorùbá mọ́- Hausa Oníṣòwò
- Nǹkan dé, Igboho ní káwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Yorùbá lọ múra ògùn jọ nítorí ohun tó ń bọ̀ lọ́nà
Daba ṣiṣẹ gẹgẹ bi agbohunsafẹfẹ ni ileeṣẹ mohunmaworan apapọ Naijiria, NTA ki o to bẹrẹ si ni mu iṣẹ ere sinima ati itage mọ iṣẹ rẹ ni nnkan bii ogoji ọdun o le diẹ sẹyin pẹlu ere ọlọsọọsẹ ni " Cockcrow at dawn"
Ni ọdun 2017 ni Daba kede pe oun ti ni aisan jẹjẹrẹ inu ẹjẹ ati jẹjẹrẹ inu koropọn ọmọ ọkunrin.
Lasiko yii, ọpọ awọn eekan ọmọ Naijiria ni wọn dide iranwọ owo fun un nigba naa.
Ni ọjọ kẹta, oṣu kẹta ọdun 2021 ni Sadiq Abubakar Daba dagbere faye ni ileewosan kan ni ilu Eko.
- Ẹ kó àwọn ọkọ̀ yín tó ti dẹnukọlẹ̀ kúrò lójú popo tàbí kí a gbẹ́sẹ̀lé wọn- FRSC sí àwọn awakọ̀
- "Sọ́jà fi ìbọn gé mi lọ́wọ́ kó lè fipá bámi lòpọ̀"
- Wọ́n tún yìnbọn níbi àpèjẹ 'Ẹ káàbọ̀' tí wọ́n ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Zamfara lẹ́yìn àṣẹ Buhari
- Wo ibi tí o ti lè fi orúkọ síìmù rẹ sílẹ̀ tàbí gba nọ́mbà tuntun tí síìmù rẹ bá sọnù
- Àwọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́bìnrin gbé ní Zamfara fẹ́ yẹ̀yẹ́ Ìjọba Buhari ni- Hadi Sirika
- Ohun tó yẹ kí ó mọ̀ nípa oríṣìíríṣìí ìlẹ̀kẹ̀ ìbàdí rè é
- Ẹ wo bí ìyàwó Pasitọ Adeboye ṣe sàpèjúwe rẹ̀
- Wo ìtàn Orunmila, Babaláwo àkọ́kọ́ àti ohun tó fi sílẹ̀ lọ níbí










