Ekiti 2022: Iṣẹ́ tí ìjọba ṣe sílẹ̀ ní a máa tẹ̀síwájú lórí ẹ torí mo ní ìrírí tó pọ̀ ni Ekiti- Biodun Oyebanji

Àkọlé fídíò, Ekiti 2022: Iṣẹ́ tí ìjọba ṣe sílẹ̀ ní a máa tẹ̀síwájú lórí ẹ torí mo ní ìrírí

Ipò òṣèlú tó kére jù ni mo ti bẹ̀rẹ̀ ní ekiti, mo mọ ohun tó kàn- Biodun Oyebanji

Biodun Abayomi Oyebanji to n dije dupo gomina Ekiti gbalejo BBC Yoruba.

O salaye ohun to pinnu lati se fun awọn oludibo ti wọn ba yan oun.

Ipo oṣelu to kere julọ ni ipinlẹ Ekiti lo ni oun ti bẹrẹ iṣẹ to si ti wa ni iriri to pọ bayii.

Ki tun ni Biodun Oyebanji tun sọ?

Oludije labẹ ẹgbẹ APC to n dari ipinle Ekiti lọwọlọwọ yii tun mẹnuba erongab rẹ fun ọrọ aje ati eto aabo ipinle Ekiti.

O ni ko si oludije to ti sise sin Ekiti bii ti oun fun ọpọlọpọ ọdun bayii.