Yollywood: Irọ́ ni o, mí o fẹ̀ Lateef Adedemeji' - Oyin Elebuibọn pẹ̀lú omijé ojú

Oríṣun àwòrán, Instagram
Gbajugbaja oṣere, Oyin Elebuibon ti ni ko si otitọ ninu iroyin pe oun ni nkan ṣepọ pẹlu akẹgbẹ rẹ, Lateef Adedeji.
Eyi ko ṣẹyin iroyin to jade pe oserebinrin Oyin Elebuibon n fẹ Lateef Adedeji, ati wi pe Lateef lo ni ọmọ ọwọ rẹ.
Amọ, ni oju opo Instagram rẹ lo ti sọ wi pe ko si ohun to jọ ọ nitori awọn oniroyin ẹlẹjẹ lo gbẹ iroyin naa jade
This article contains content provided by Instagram. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read Instagram cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of Instagram post, 1
O ni inu ọkọ oun ati baba oun kodun si iroyin naa, ati wi pe kini oun fẹ salaye fun awọn ololufẹ oun.
- Mo pàdánù owó tó lé ní N20m lọ́jà Shasha, mi ò padà síbẹ́ mọ́- Alhaji Nyako
- "Èèyàn mọ́kànlá ni a yìnbọn pa níbi ìdigunjalè Offa"
- Wo oríṣi oúnjẹ márùn ún tí kò wọ́pọ̀ ṣùgbọ́n tí àwọn kan fẹ́ràn púpọ̀ ní Nàìjíríà
- Ọwọ́ pálábá Abubakar, mọ́káliíkì ségi níbi tó ti fẹ́ jí ọkọ̀ gbé l'Abuja
- Kí ló mú kí géńdé Olorun fi àfọ́kù ìgò gé ǹkan ọmọkùnrin rẹ̀ ní Kano?
- Ìjọba Naijiria ti kùnà lórí ojúṣe rẹ̀ lóri ètò aàbò- Bode George
O ni oun to ṣẹlẹ ni wi pe awọn ọrẹ oun lọ sọ wi pe ki oun fi orin aladun ki Lateef ti oun ṣe ọjọ ibi ti oun si kii fun ayẹyẹ ọjọ ibi naa.
This article contains content provided by Instagram. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read Instagram cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of Instagram post, 2
O ni ko si ọrọ ifẹ tabi ibaṣepọ kankan laarin wọn bi ko ṣe ti oṣere si oṣere.
Bẹẹ si ni Lateef kọ lo ni ọmọ oun, ati wi pe irọ lasan ni.
Lẹyin to fi iroyin naa lede, ọpọlọpọ awọn ololufẹ rẹ lo n kii pe ki o ye sunkun, nitori awọn oniroyin ẹlẹjẹ.
Oyin Eleibuibọn jẹ gbajugbaja oṣere, ti baba rẹ, Yemi Elebuiboon si jẹ onimọ ifa ti ọpọlọpọ eniyan mọ daradara ti wọn si fẹran ji ilẹ Yoruba.
- Ìjọba Naijiria ti kùnà lórí ojúṣe rẹ̀ lóri ètò aàbò- Bode George
- Èèyàn 627 ni COVID-19 ti pa ní Nàìjíríà láàrín oṣù Dìsẹ́mbà sí àsìkò yìí, 16 ló kú l'Ọ́jọ́bọ̀ nìkan
- A kò tíì gbọ́ pé ilé ẹjọ́ wọ́gilé gbígba owó lọ́wọ́ àwọn dẹ́rẹ́bà ni ibudokọ ipinlẹ Oyo- awọn Awakọ̀
- Akẹ́kọ̀ọ́ ọmọ ọdún mẹ́rìnlá mú ìbọn ìléwọ́ lọ ilé ìwé láti yìín lu olùkọ́ tó ní kó gé irun orí rẹ̀
- Alhaja Muslimot Salami tí àwọn darandaran kọlù ní Ogun tí padà jẹ́ Olorun nípè!
Ilu London ni Ilẹ Gẹẹsi ni Oyin Elebuibọn n gbe, to si ti kopa ninu ọpọlọpọ ere sinima.













