Nigeria police ban: Ọlọ́pàá fòfin de lílo "siren" àti "tinted glass" lọ́nà àìtọ́

Oríṣun àwòrán, @Nigeria Police
Ọlọ́pàá fòfin de lílo "siren" àti "tinted glass"
Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá fòfin de lílo"siren" àti "tinted glass
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Adamawa ti fòfin de lilo sinrin ati gilaasi dudu(tinted glass) to fi mọ nọmba ti wọn da nkan bo nipinle naa.
- Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti f'òfin de ìpéjọpọ̀ tó bá ju àádọ́ta (50) èèyàn lọ torí ọwọ́jà kejì coronavirus
- Ǹkan tÍ Sunday Igboho ṣe ní Ibarapa tún ti ṣelẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun- Olórí Miyetti Allah ilẹ̀ Yorùbá
- Mínísítà ètò ìròyìn nígbà kan rí Tony Momoh dágbére fáyé lẹ́ni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin
- 'Ẹ yé bú Seyi Makinde, owó rẹ̀ ló fí ra Ọkọ bọ̀gìnì fún Alhaja Abosede Adedibu, Taye Currency, Mutiat Ladoja'
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Adamawa, DSP Suleiman Nguroje lo f'ọrọ yii lede ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Iṣẹgun.
Nguroje ṣalaye pe awọn nkan yii le ṣi awọn oṣiṣẹ eleto abo lọna ati pe wọn tun le dẹru ba awon eeyan nipinle ọhún.
O fikun ọrọ rẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa n ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ẹṣọ alaabo mii lati ri pe iwa ọdaran di afiseyin bi eegun n fi aṣọ ni Adamawa.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni awon agbofinro ti bẹrẹ si ni dawọn awakọ duro lati ṣe àwárí awọn ọdaran to n da ilu ru.
- 'Ẹ yé bú Seyi Makinde, owó rẹ̀ ló fí ra Ọkọ bọ̀gìnì fún Alhaja Abosede Adedibu, Taye Currency, Mutiat Ladoja'
- Ọmọ ọdúnmẹ́tàdínlógún káwọ́ sẹ́yìn rojọ́ lórí ẹ̀sùn ìdúnkookò láti gbẹ̀mí ìyá rẹ̀''
- Seyi Makinde fi ọkọ̀ ńlá mẹ́rin dá ikọ̀ Amotẹkun lọ́lá nípìnlẹ̀ Oyo
- Ǹkan tÍ Sunday Igboho ṣe ní Ibarapa tún ti ṣelẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun- Olórí Miyetti Allah ilẹ̀ Yorùbá
- Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ mú àgùnbánirọ̀ di èrò iléẹjọ́ ní ìpínlẹ̀ Kogi
O ni: "Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Adamawa fi n da awọn eeyan ipinlẹ naa loju pe abo to peye yoo wa fun wọn lọdun 2021," Nguroje lo sọ bẹẹ.
O rọ awọn eeyan ipinlẹ naa lati fọwọ so ọwọ pọ pẹlu awọn agbofinro lori ọrọ eto aabo.
- Àwọn dókítà Ondo bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ
- Ilẹ̀ Amerika ń wá olùkọ́ èdè Yorùbá, wo bí o ti lè forúkọ sílẹ̀ níbí
- Ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ní pé wọ́n pa ọmọ ogun mẹ́fà tó jẹ́ iran Igbo nikọ̀kọ̀ ní Abuja- Iléeṣẹ́ ológun
- Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti f'òfin de ìpéjọpọ̀ tó bá ju àádọ́ta (50) èèyàn lọ torí ọwọ́jà kejì coronavirus














