Itunu Babalọla Death: Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Baba Itunu Babalọla,Abayomi ko le e pa ibanujẹ rẹ mọra lasiko to n sọ ohun ti oju ọmọ rẹ ri ni ọgba ẹwọn ti wọn fi si ni orilẹede Côte d'Ivoire ko to di oloogbe.
Baba rẹ ṣe apejuwe ọmọ rẹ gẹgẹ bi ẹni to n pese ounjẹ oojọ fun awọn nitori iya rẹ wa lori idubulẹ aisan.
''Ọdun 2019 to wa si ile lati wa ba wa se ọdun ni ekeji rẹ ti wọn jọ n gbe ile pe e pe ole jawọ ile wọn, pe ko si ma a pada bọ.''
BBC Yoruba kan si Arabinrin Abike Dabiri to jẹ adari ileeṣẹ to n ri si ọrọ awọn ọm Naijiria to wa lẹyin odi lori bi baba Itun ṣe n beeere fun oku ọmọ rẹ yii, esi to fun wa wa ninu ọrọ ori foonu to ba wa sọ yii : Èsì ìjọba Naijiria rèé sí Baba Itunu Babalola tó ń béèrè fún òkú ọmọ rẹ̀ àti irú ikú tó pa á
- Wọ́n lù mí bíi ẹní máa kú, wọ́n ya aṣọ mọ́ mi lọ́rùn nílé Princess kí n tó dé àgọ́ ọlọ́pàá - Baba Ijesha
- Lẹ́yìn Titi Masha, Kwam 1 gbé ìyàwó tuntun, Emmanuella Ropo l'Abeokuta, bó ṣe lọ rèé
- Àwọn alamí ìjọba kan ti wà láàrín àwa ajìjàgbara Yoruba Nation tó ń bínú pé Sunday Igboho ti ga ju àwọn lọ - Akintoye
- Ilééṣé ọlọ́pàá Osun tí mú Olùdarí ilé ìtura tí Akẹ́kòó fásìtì OAU ti dédé pòórá
- 'Ó ṣeéṣe kí ẹ̀dà ìwé àbájáde ìwádìí ìgbìmọ̀ EndSARS tó lu sórí ayúlujára yàtọ̀ sí èyí t'íjọba yóò gbé jáde'
- APC kéde N22.5m owó fọ́ọ̀mù fáwọn tó fẹ́ díje fún ipò gómìnà l'Osun àti Ekiti
- Òhun tí Cute Abiola ṣe rèé táa fí sọ ọ́ sí àhámọ́ - Iléeṣẹ́ Navy
- Wo Femi Otedola, Mr Eazi, E-money, Eniola Badmus, Ikorodu bois àtàwọn èèkàn tó ti fowó ránṣẹ́ sí Davido
- Èèyàn mẹ́rin kú sábẹ́ ilé alájà kan tó dàwó ní Badagry
- Nítorí òbítíbitì ìdọ̀tí la ṣe ti ọjà Oyingbo pa - Folashade Tinubu-Ojo
Ẹkunrẹrẹ fidio yii sọ bi Itunu Babalola se de ọgba ẹwọn, to si n beerẹ fun idajọ ododo...