Ekiti 2022: A ti ṣètò aàbò tó péye fún Olùdíje, Olùdìbò àti Oṣìṣẹ́ INEC ni ekiti- Kokumo
Aabo to daju wa fun gbogbo eeyan Ekiti titi dèyìn igba ti wọn ba kede ẹni to jawe olubori- Oga Olopaa Kokumo.
Gbogbo Abiyamọ, ẹ fa ọmọ yin leti ni Ekiti- Oga Olopaa Johnsoon Babatunde Kokumọ.
Oga agba Johnson Babatunde Kokumọ to jẹ adari gbogbo ikọ agbofinro to n mojuto eto idibo Ekiti lonii.
- Abiyamọ Ekiti, ẹ fá ọmọ yín létí lónìí- Ọ̀gá ọlọ́pàá Ekiti
- Wo ọ̀nà tí wà á gbà dé ibùdó ìdìbò rẹ̀ níbikíbi ni Ekiti
- Mọ̀ síi nípa olùdíjé gómìnà Ekiti mẹ́rin tí ayé ń pariwo lórí ayélujára báyìí
- Nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Olaniyi Ben Agboola, olúdíje ẹgbẹ́ PRP nínú ìdìbò gómìnà ipinlẹ Ekiti
- Iṣẹ́ máa wà lọ́pọ̀ yanturu l’Ekiti tí mo bá di gómìnà - Adeyinka Ali, olùdíje ẹgbẹ́ APP
- Wo àwọn nǹkan mẹ́wàá nípa olùdíje sípò gómìnà Ekiti lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ òṣèlú Labour Party
- Wọ́n ti fi owó Ekiti ṣòfò yànfùyànfù sẹ́yìn ní ìya ṣe ń jẹ wa ní Ekiti- Oluyede
- Mo mọ eèyàn Ekiti dáadáa, òye ìjọba dẹ̀ yé mi- Biodun Oyebanji APC Ekiti
- Ǹjẹ́ o mó Oladosu, ọmọ Peter Fatomilola tó jẹ́ olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú NNPP-
- Ayé àwọn èèyàn Ekiti dára nígbà tí wọ́n wà lábẹ́ Ondo ju ìsìnyí lọ- Reuben Famuyibo Accord
Johnson Babatunde Kokumo salaye pe eto aabo to peye ti wa fun awọn Oludije, Oludibo, Oṣiṣẹ eleto idibo INEC, ati awọn ara ilu Ekiti lapapọ.
O ni pe awọn yoo duro gbagi ni Ekiti titi deyin ti wọn ba kede eni to bori.