Ekiti 2022: Kìí ṣe gómínà nìkan ni Ekiti nílò báyìí fún ọjọ́ ọ̀la tó dára- Oluwole Oluyede
Ẹ̀gbẹ́ ADC lo le fọwọsowọpọ yanju iṣoro Ekiti bayii- Oluyede
Akọṣẹmọṣẹ oniṣegun oyinbo ni Oluwole Oluyede to n dije dupo gomina Ekiti labẹ asia ẹgbẹ oselu African Democratic Congress.
O sọrọ lori awọn aṣiṣe to ti waye ninu isejọba ipinlẹ Ekiti tẹlé ati ohun to yẹ ni ṣiṣe bayii.
- Ǹjẹ́ o mó Oladosu, ọmọ Peter Fatomilola tó jẹ́ olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú NNPP-
- Nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Olaniyi Ben Agboola, olúdíje ẹgbẹ́ PRP nínú ìdìbò gómìnà ipinlẹ Ekiti
- Olóṣèlú ni mí, mo mọ ìṣòro àwọn ará Ekiti- Bisi Kolawole PDP
- Ajagunigbala Moses Olajide, pásítọ̀ tó fẹ́ di gómìnà ipinlẹ Ekiti lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ AAC
- Ayé àwọn èèyàn Ekiti dára nígbà tí wọ́n wà lábẹ́ Ondo ju ìsìnyí lọ- Reuben Famuyibo Accord
- Ìtẹ̀síwájú àwọn eèyàn Ekiti ló jẹ́ mi lógún- Kemi Elebute Halle
Oluwole Oluyede ti ẹgbẹ ADC tun sọ nipa ọna abayọ si isọrọ awọn eniyan Ekiti lasiko yii.
O menuba awọon nkan to fẹ se lọna to yatọ ni ipinle Ekiti.
O ni ifọwosopọ lo le ko Ekiti yọ ti ẹgbẹ rẹ si duro fun.