Issa Aremu ṣàlàyé kíkún nípa èròńgbà ẹgbẹ́ Labour to bá jáde
O ṣakawe nipa àwọn agba oloṣelu ati iṣẹ wọn fun BBC Yoruba lasiko ifọrọwanilẹnuwo naa.
Issa Arẹmu ti figba kan jẹ igbakeji aarẹ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ti a mọ si Nigeria Labour Congress.
O n dije dupo gomin alabẹ ẹgbẹ oṣelu Labour Party ni Kwara.
- Ẹgbẹ́ APC dá ọmọ Alao Akala padà sípò alága Ogbomọṣọ North
- Ọjọ́ Àbámẹ́ta la ó mọ ẹni tí yóò lékè láàrín bàbá ìsàlẹ̀ àti àwọn mẹ̀kúnnù nipinlẹ̀ Ọyọ. – Seyi Makinde
- Ètò tí mo ní fún Kwara yàtọ̀ sí ti ANRP ni mo ṣe fẹgbẹ́ wọ́n sílẹ̀ - Yinka Ajia
- 2019 Elections: NBC na Channels TV àti ilé iṣẹ́ ìròyìn 44 ní pàsán
Bi ọmọ kò bá ba itan, o di dandan kó ba àrọ́bá to jẹ́ baba ìtàn, Issa Arẹmu ṣalaye fun BBC pe oloṣelu to fẹ ṣaṣeyọri gbọdọ ṣetan lati sin awọn eniyan rẹ ni.
O fi Oloye Ọbafẹmi Awolowọ ati Saudana Sokoto ṣe akawe awọn oloṣelu ti ipa wọn ko le parẹ lai.
Issa Arẹmu ni ẹni to ba laya lo n dije dupo.
O mẹnuba gbogbo nkan ti oun ati ẹgbẹ rẹ ni lọkan lati ṣe fun awọn eniyan ipinlẹ Kwara ti oun ba wọle.
- Ohun márùn-ún tí Atiku ń bèrè lọ́wọ́ Buhari níbi ìpàdé rẹ̀ pẹlú Abdulsalam, Kukah
- APC pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílé fún Amosun, Okorocha
- Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ọdọ 43m ló wà lára olùdìbò?#BBCNigeria2019
- #BBC Nigeria Decides: Akala darapọ̀ mọ́ APC fún ìbò gómìnà
- #BBCNigeria2019: BBC ṣetán láti mu gbogbo ètò ìdìbò bó ṣe n lọ wa!