Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọ́lù ú
Bi o ba lo ọdun mẹtadinlogun lọgba ẹwọn lori 'ẹṣẹ aimọdi, Ta ni o maa pe lẹjọ?
Irinajo Adebayo Ojo lati ilu Ọgọtun Ekiti ni BBC Yoruba mu wa loni.
Adebayo to n ṣiṣẹ oko alagbaṣe fi ran ara rẹ nile iwe titi to fi kawe de ile iwe giga Owo Poly lo ko sọwọ agbofinro lori ẹṣẹ aimọdi to si ti ibẹ gba idajọ iku.
O ni wọn ni oun digunjale pẹlu awọn awọn eeyan kan lati ja Omolade Yemi lole, eyi to sọọ di ero SARS
- Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko
- Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú
- Bàbá ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ
- Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran
- Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀...
- Ìṣẹ́ ló jẹ́ kí n sọ ọmọ nù sórí ààtàn- Dupẹ, Ìyá Muiz
Adebayo Ojo ni lati Ilawẹ Ekiti lọ si ọgba SARS ni Ado Ekitit ko to di ero Maximum Security Prison ni eko ni irinajo yii
O ni lọdun 2003 ni oun ti ko sii ko to bọ ni 2019.
2005 ni wọn dajọ iku fun un, ṣugbọn gomina Fayose ni oun ko le bu ọwọ lu iwe iku ẹlomii.
Tomale Akinbanji, to jẹ ọrẹ Ojo sọrọ ilẹ kun fun BBC lori iṣẹlẹ arinfẹsẹsi yii.
- Èèyàn 125 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà
- Ìjọba Nàìjíríà ti kéde pé kí ilé ìtura ṣí padà, kí ìlé ìwé máa palẹ̀mọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́
- Ara ló ń ta àwọn ẹgbẹ́ NURTW tó ń pariwo mi kiri, APC ni wọ́n bá lọ nígbà náà l'Oyo- Auxiliary
- Daniel Prude: Ìbòjú tí àwọn ọlọ́pàá New York fi bo ọkunrin ọhun ló ṣe ikú pà á
- Mo ṣetán láti fi ẹ̀ṣẹ́ dín dòdò ìyà fún Anthony Joshua- Efe Ajagba
Adebayo Orisameyitimi to jẹ baba Ojo ni Ọgọtun Ekiti naa sọrọ pe diẹ lo ku ki oun ku nitori airi owo gba lọya fun Ojo
Ọjo ṣalaye bi o ṣe kawe pada lati J S 3 pẹlu iranlọwọ Cottage of Hope Institute ninu ọgba ẹwọn to fi kawe gboye jade ninu Criminology ni National Open University .
- Wo ohun tó ń fa àfikún epo lóòrèkóòrè ní Nàìjíríà
- Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana
- Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á
- E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
- Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ
Ojo sọ ipa ti Al-Mustapha kó fun oun nigba ti wọn jọ wa lẹwọn ati ajọ JLAA ati agbẹjọrọ Kingsley Ughe Esq tó pada kọwe si gomina Fayemi nigba to de ori aleefa.
Gomina Fayemi lo pada tu Ojo silẹ pẹlu agba ra ipo rẹ.
Gbogbo eeyan n beere iranlọwọ iṣẹ fun Ojo Adebayọ lasiko yii.

