Lebanon returnees: Àwọn aláànú àti ìjọba Lebanon ló san owó tí a fi ń kò àwọn ọmọ Nàìjíríà tó há sí Lebanon padà- Dabiri
Abike Dabiri: Ajo ko dabi ile, ẹ jẹ ki gbogbo wa tun Naijiria ṣe.
Abike Dabiri to jẹ olubadamọran pataki fun Aarẹ Buhari lori ọrọ ilẹ okeere ṣalaye fun BBC ibi ti iṣẹ de duro lori kiko awọn ọmọ Naijiria to ha si Oman ati Lebanon wa sile lasiko ajakalẹ arun coronavirus yii ati iṣẹlẹ ibugbamu to waye ni Lebanon.
- Wo díẹ̀ nípa ohun tí Walter Carrington gbé ṣe nígbà ayé rẹ̀
- Ẹgbẹgbẹ̀rún ọmọ Nàìjíríà ní yóò má a kú lójoojúmọ́ tí wọn bá gbà wọ́n láàyè láti gbébọn dání- Amofin
- Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020
- Ilé iṣẹ́ tó ri si ètò ẹ̀kọ́ l'Abuja kò tí ì rànsẹ́ pé UNILAG ti ni Giwa tuntun
Awọn ti Naijiria ko de tẹlẹ ti fi ayọ wọn han si Oluwa ati Naijiria.
Dabiri ki Makinde, Sanwo Olu ati Oyetola ku iṣẹ iranlọwọ ti wọn n ṣe lati ri awọn ọdọ yii ko wa sile pada.
O kilọ pe ki gbogbo ẹbi maa kilọ fun awọn ọmọ wọn ki wọn yẹra fun ẹtan pe orilẹ ede miran dara ju Naijiria lọ.
- Ohun gbogbo tí mò ń rí ní ààfin tẹ́ mi lọ́rùn, èmí ní mo ní ayé mi- Olori Aanu
- Ṣé ìrànwọ̀ ni Kamala, ìgbákejì tí Biden yàn yóò jẹ́ fún un tàbí ìpalára?
- Èèyàn 334 ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 l'Ọjọru, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀- NCDC
- Ìbejì wù mí láti kékeré ṣùgbọ́n mí ò mọ̀ pé ìbẹfà lorí kọ mọ́ mi- Ifeoma Ìyá Ìbẹfà
O ni Lebanon ti ni ko si fisa mọ fun awọn ọmọ Naijiria lati wa ṣe ọmọ ọdọ nibẹ mọ.
Dabiri ṣalaye pe awọn alaanu ati ijọba Lebanon lo san owo ti Naijiria fi ko awọn to m bọ lalẹ yii gan an wa sile.
Ọfẹ si ni awọn ọmọ naa n de laisan kọbọ kan funra wọn.

