Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua
Kí ede ati àṣà Yoruba ma baa parun ni a ṣe da BBC Yoruba silẹ ni Naijiria.
Aina òrósùn ni ọkan ninu awọn orukọ amutórunwa ti ọmọ Yoruba n jẹ bii oriki.
Erongba BBC Yoruba ni ki ede, aṣa ati igbagbọ iran Yoruba ma parun ni a ṣe jade lọ beere nipa awọn Aina ki a tun fi rán ara wa leti iru ọmọ to n jẹ Aina.
- ‘Mo ké bòòsí tòò bí mo ṣe bí ìbejì, ti ọ̀kan jẹ́ àfín, ìkejì jẹ́ dúdú’
- Aisha Binani di obìnrin àkọ́kọ́ tó gbégbá orókè láti dupò gómìnà lọ́dún 2023
- Èèwọ̀ ni láti pa ẹja nínú odò Sogidi ni Aáwẹ́ nipinlẹ Oyo
- Ìdí mẹ́rin rè é tí dọ́là ẹyọ̀kan ṣe di 600 naira ní Naijiria
- Ǹkan tí àwon omo Naijiria ń so nípa ''delegates'' tó ń dìbò fún egbé òsèlú ní yìí...
- Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan
Aina ni ọmọbinrin ti o gbe ibi kọrun wa sile aye nigba ti a bi i.
Wọn maa n sọ ọmọkunrin to ba gbe ibi kọrun wa sile aye ni Ojo.
- Àrùn measles ṣekúpa ọmọdé mẹ́rìnlá ní ìpínlẹ̀ Anambra
- Kété ti ijọ̀ba ba ṣàtúnṣe sójú òpópónà ni ìjínigbé á dínkù -Awakọ̀
- Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀tọ̀ lórí àwọn tó pin gàrí, ṣúgà àti mílíkì níbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ
- Àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń dọdẹ àwọn obìnrin òde òní
- Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀tọ̀ lórí àwọn tó pin gàrí, ṣúgà àti mílíkì níbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ
Ẹya Ijẹbu ni ipinlẹ Ogun ni guusu Naijiria kii sọ ọmọkunrin wọn ni Ojo.
Ati obinrin, ati ọmọ ọkunrin to ba ti gbe ibi kọrun wa saye, Aina ni wọn maa n sọ wọn.
Wọn ma n ki awọn Aina pe:
"Aina Ogunyunmọla
A dá ilá ọkọ re
A se ọbẹ̀ ọkọ lọ́tọ̀
Ebi kìí pa ọkọ Aina òrósùn rara
Iná dídá kìí ni wọn lára nitori ọkọ....."
Ọpọ eniyan lo gbagbọ pé awọn Aina maa n ni ìpinnu to ga ti ko rọrun fun ẹlomii lati yipada fun wọn.