Mike Tyson Canabis ambassador: Malawi kọ lẹ́tà sí Mike Tyson pé kó di asojú wọn fún ewé ọlà, igbó

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileese eto ọgbin lorilẹ-ede Malawi ti kọwe ẹbẹ ransẹ si Mike Tyson pe ko di asoju awọn lori ọrọ Igbo.
Mike Tyson to jẹ gbajugbaja abẹsẹkubi ojo ni ti gba iwe ifẹ lati ọdọ ileesẹ ijọba apapọ orilẹ-ede Malawi to n ri sio eto ọgbin.
Won ni ki Mike Tyson jọwọ ara rẹ gẹgẹ bii asoju wọn lori ọra Igbo to jẹ ewé ọlà.
- "Lẹ́yìn ti mo lo ọdún 42 lọ́gbà ẹ̀wọ̀n, wọ́n tú mi sílẹ̀ pé ń kò jẹ̀bi ẹ̀sùn ìpànìyàn"
- Àlàyé ọlọ́pàá Osun rèé lórí ọ̀nà tí Rahmon Adedoyin gbà ká ọ̀rọ̀ rẹ̀ sínu fọ́nrán ohùn tó lu ayélujára pa
- Èèmọ̀! Bíṣọ́ọ́bù bá ọmọ tuntun lórí pẹpẹ ṣọ́ọ̀ṣì, láì mọ ẹni tó ni
- Bàbá mi máa ń sunkún torí bí kò ṣe le padà ṣeré tíátà mọ́ - Ọmọ Baba Suwe
- Clem Ohameze, òṣèré tíátà ní àìlera, ó ń bẹ̀bẹ̀ àdúrà lórí iṣẹ́ abẹ
- N kò rán ẹnikẹ́ni láti pín ìrẹ̀sì àti ẹ̀wà tórí ìbò ààrẹ 2023 - Bola Tinubu figbe ta
- Ẹ màá múra sílẹ̀ láti ra lítà epo kan ní ₦320 sí ₦340 lọ́dún 2022- NNPC
- Tówẹ́ẹ̀lì ni bàbá mi ró mọ́ ìdí nígbà tí àwọn sọ́jà wọlé mu lọ - Ọmọ Akintunde
- Jàndùkú kọlù mi, gé mi lára bíi olè torí mo jẹ́rìí tako ìjọba níbi ìwádìí ìpànìyàn Endsars Lekki''
- Femi Fani-Kayode ṣàlàyé bí ìrìnàjò rẹ̀ sọ́dọ̀ EFCC ṣe jẹ́
Minista Lobin Lowe salaye nipa bi Igbo se di eyi ti ofin Malawi faaye gba nile ati nita orilk-ede Malawi.
Ileese eto ọgbin naa ni pe Egbẹ United States Cannabis Association naa lọwọ si ipe lati soju naa.
Ogbẹni Lowe so pe olokowo naa ni Mike Tyson ati pe oun naa ni oko Igbo to ti na owo si to pọ.
'Malawi Gold' to jẹ wura Malawi ni orukọ ti wọn n pe Igbo ni Malawi.
Ọdun 1985 ni Mike Tyson bẹrẹ abẹṣẹkubi ojo, ko to fẹyinti lọdun 2005.














