Sunday Igboho: Ìjọba Buhari ló ní ẹ̀bi, ẹ yé dá ẹ̀bi ru àwọn tó ń bèèrè fún 'Yoruba Nation'
Olugbọn ti Orile-Igbọn, Ọba Francis Alao ti kesi awọn lọbalọba ni ilẹ Yoruba lati maṣe sọ ọrọ ''Yoruba Nation di ọrọ oṣelu.
Ọba Francis lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni ohun gbogbo ni wọn ti ọrọ eto aabo to dẹnukọlẹ lorilẹede Naijiria lo yẹ ki aarẹ Buhari dojukọ kii ṣe Sunday Igboho tabi Nnamdi Kanu.
Olugbọn ni iya ati iṣẹ ti ohun ba awọn ọmọ Naijiria finra lo jẹ ki awọn eniyan ma a lọgun lati da duro gẹgẹ bi ẹya.
- À ń wá Gbajúmọ̀ apanilẹ́ẹ̀rín, Cute Abiola o! A kò gbúrò rẹ̀ nílé - Mọ̀lẹ́bí
- Àwọn ọlọ́jà ní Oyingbo ṣe iwọ́de, wọ́n ní Folashade Tinubu ti ọjà pa torí N5m
- Iléeṣẹ́ Navy dákẹ́ lórí ibi tí Cute Abiola há sí àmọ́ àṣírí tí agbẹjọ́rò rẹ̀ tú fún BBC rèé
- 'Kò sí nkan tó burú nínú bí Akeredolu ṣe yan ọmọ rẹ̀ sí ipò! Ayé ń ṣe irú ẹ̀'
- Ilé ẹ̀kọ́ Fásítì Unilorin fọwọ́ òsì júwe ilé fún akẹ́kòó tó lù olùkọ lálùbami
- Lóòtọ́ ni wọ́n de òkú táa gbé jáde nínú odò Asa, Ilorin lọ́wọ́ àti ẹnu - Ilééṣé ọlọ́pàá
- Wo bí ọ̀rọ̀ ikú ọmọbìnrin tó fẹ́ fa àríyànjiyàn láàrín Nàìjíríà àti Ivory Coast ṣe jẹ́
- Ọgbọ́n ni mo ń dá láti yẹra fún gbọ́yísọ̀yí lágbo òṣèré - Ijebu
- Ta lo tún ti ilé ijó Obi Cubana l'Abuja pa?
- Ogún ọdún ṣẹ́yìn ló yẹ kí n gba SAN tí wọn kò fún mi - Àjàgbé Toriola Oyewo sọ bó ṣe di amòfin àgbà lẹ́ní ọdún 90
Olugbọn ti Orile-Igbọn, Ọba Francis Alaorọ Aarẹ Buhari lati tun orukọ rẹ ṣe nitori kii ṣe Buhari ti awọn mọ ni ọdun 1980 ni eleyii mọ.
Ẹ wo ẹkunrẹrẹ fidio naa fun ero Ọba Francis lori idibo sipo aarẹ ni ọdun 2023.