Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já ìbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
Ninu aworan yii, obinrin kan sọ iriri rẹ lori bi o ṣe la iwa ifipa ṣe ayẹwo funni lọgba ẹwọn labẹ awawi a n ṣe ayẹwo abale funni.
Bi o tilẹ jẹ pe ko si imọ sayẹnsi to gbe e lẹsẹ, o le ni ogun orilẹede ti awọn ayẹwo abale ti wọn n fipa ṣe yii ti n waye gẹgẹ bi ajọ iṣọkan agbaye ṣe sọ.
Ileeṣẹ BBC lede larubawa, BBC Arabic ba Esra, ọkan lara awọn to tii ṣe ẹwọn ri nitori ọrọ oṣelu lorilẹede Egypt sọrọ; o si ṣalaye iriri rẹ nipa ayẹwo ibale afipa ṣe lasiko to fi wa lọgba ẹwọn.
A yi orukọ rẹ pada lati daabo bo.
- Háà! Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta
- Ọ̀pọ̀ ọkùnrin ló máa ń wò mí ní àwòyànu pé obìnrin ń ṣe 'Welder'- Omolola
- Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba tí ajé ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí
- Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago? Nkan tí a mọ̀ nìyíì
- Ariwo lásán ni Dádì àti Mọ́mì rò pé mó ń fi ike pa tẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n ó ti sọ mi di èèyàn ńlá báyìí
- Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat
- Kìí ṣe gbogbo èèyàn ló lè máa jẹ irú mi- Adebola, Iya Adigun onírú ìgbàlódé fárígá
- Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria Kolawole
- Ìwà ìbàjẹ̀ bíi olé jíjà, ìjínigbé àti rìbá gbígbà ní Okediji fi ṣàpèjúwe ǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà
- Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù